Aliko Dangote

Gbajumo Onisowo

Aliko Dangote Ha-Aliko Dangote.ogg listen GCON (ojoibi 10 April 1957) jẹ́ onísòwò àti ọlọ́rẹ ará Nàìjíríà tí ó olùdásílẹ̀ àti alága ilé-isẹ́ Dangote Group, ilé-isẹ́ aloẹ̀rọ gbàǹgbà ní Áfríkà.[2]

Alhaji
Aliko Dangote
MFR, GCON
Dangote at the World Economic Forum, 2011
Ọjọ́ìbíAliko Dangote
10 Oṣù Kẹrin 1957 (1957-04-10) (ọmọ ọdún 67)
Kano, Northern Nigeria,
British Nigeria
(now Kano, Nigeria)
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ẹ̀kọ́Government College, Birnin Kudu
Iléẹ̀kọ́ gígaAl-Azhar University, Cairo
Iṣẹ́Industrialist and philantrophist
Ìgbà iṣẹ́1977—present
Gbajúmọ̀ fúnFounding and leading the Dangote Group
Net worthUS$7.7 billion (April 2020)[1]
Àwọn ọmọ3 daughters including Halima Dangote;

Gbogbo ohun ìní rẹ̀ ẹ́ tó US$8.1 billion (March 2020)[1], ní January 2020, òhun ni ẹni ọlọ́lájùlọ 88k ni agbaye àti ẹni ọlọ́rọ̀ jùlọ ní ilẹ̀ Áfríkà.[3]

Ní Oṣù kọkànlá ọdún 2021, Sani Dangote, Igbákejì Alákoso (VP) ti Ẹgbẹ́ Dangote àti àbúro Aliko Dangote, kú.



Itokasi àtúnṣe

  1. 1.0 1.1 "Aliko Dangote". Forbes. Retrieved 16 October 2019. 
  2. "History & Strategy – Dangote Industries Limited" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-03-15. 
  3. Nsehe, Mfonobong (5 March 2013). "The Black Billionaires 2013". Forbes. Retrieved 3 May 2015.