Túndé Aládéṣe jẹ́ olùkọ̀tàn tí ó sì tún ti gba àmì-ẹ̀yẹ ti Africa Movie Academy Award for Best Actress in a Leading Role ní ọdún 2018.[1]Ó ti kọ ìtàn ti a 70 night drama fún MTV Shuga filmed by the actors themselves over four countries, explaining and set during the coronavirus lockdown .

Screenshot from the final 70th episode of MTV Shuga Alone Together

Iṣẹ́ rẹ̀ àtúnṣe

Aládéṣe ti nífẹ́ sí eré orí-ìtàgé láti ìgbà tí ó ti wà ní ilé-ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bérẹ̀ níbi tí ó ti dara pọ̀ mọ́ àwùjọ ẹgbẹ́ òṣèré tí ó sì fẹ́ràn orin kíkọ pẹ̀llú. Ó kẹ́kọ́ nìmọ̀ nípa eré-oníṣe nínú èdè Gẹ̀ẹ́sì (English Literature) ní Yunifásitì Ìbàdàn .[2] Ó tú kẹ́òọ́ nípa eré orí-ìtàgé ní Met Fi School ní ìlú Lóndọ̀nù,.[2]

Aládéṣe ti kọ ìtàn fún Edge of Paradise àti Tinsel.[3] She was the head writer for the series Hotel Majestic.[4] Àjọ [YNaija]] kàá mọ́ àwọn ọmọ ogójì ọdún tí wọ́n ń kópa ribiribi ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[5] Ní ọdún 2018, ipa tí Aládéṣe kó nínú eré The Lost Cafe' gẹ́gẹ́ bí Kenneth Gyang ni wọ́n fi yàn án fún Africa Movie Academy Awards gẹ́gẹ́ bí òṣèré tó peregedé jùlọ .[6] Aládéṣe ma ń kọ eré àtìgbàdégbà fún MTV Shuga, nígbà tí wọ́n pe àwọn ọlọ́kan-ò-jọkan eré Ṣúgà ní Shuga Down South. Ó kọ ìsọ̀rí méjì fún iṣẹ́ náà ṣáájú kí wọ́n tó yàn án gẹ́gẹ́ bí olóòtú àgbà fún iṣẹ́ àkànṣe náà. [7] Ní àsìkò àjàkálẹ̀ àrùn Covid-19, wọ́n ní kí ó kọ ìsọ̀rí eré olójojúmọ́ fún MTV Shuga Alone Together kí ó sì sọ ipa àti ìdààmú tí àrùn Kòrónà ń mú bá àwọn ènìyàn. Wọ́n fi eré náà hàn ní ogúnjọ́ oṣù Kẹrin ọdún 2020.[8]Wọ́n ṣe eré náà ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, South Africa àti Cote D’Ivoire.[7] The series was planned to last for 65 episodes.[2]

Àwọn fíímù rẹ̀ àtúnṣe

Àwọn àmì-ẹyẹ tí ó ti gbà àtúnṣe

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "10 things you didn't know about 'Hotel Majestic' head writer". Pulse. Retrieved 2019-08-09. 
  2. 2.0 2.1 2.2 Jack, Fisher (2020-07-01). "Nigerian Actress / Screenwriter (Tunde Aladese) Writes Coronavirus Hit African Lockdown Series – Sponsored by UN". EURweb (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-07-02. 
  3. "#TheYNaijaInterview: I never expected to make a living from writing in Nigeria – Tunde Aladese". January 28, 2015. Retrieved 2019-08-15. 
  4. "10 things you didn't know about 'Hotel Majestic' head writer". Pulse Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2015-02-24. Retrieved 2020-04-30. 
  5. "Gyang, Genevieve, others are 10 most powerful under 40s". Dailytrust. Archived from the original on 2019-08-09. Retrieved 2019-08-09. 
  6. Shaibu Husseini (August 11, 2018). "Africa’s screen and acting first ladies slug it out at AMAA". The Guardian (Nigeria). Retrieved 2019-08-15. 
  7. 7.0 7.1 Akabogu, Njideka (2020-04-16). "MTV Shuga and ViacomCBS Africa Respond to COVID-19 with "Alone Together" Online Series". BHM (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-04-30. 
  8. "Every Woman Every Child partners with the MTV Staying Alive Foundation to Tackle COVID-19". Every Woman Every Child (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-04-16. Archived from the original on 2021-10-09. Retrieved 2020-04-30. 
  9. "Spotlight on Tunde Aladese". Nollywood Observer. November 24, 2016. Archived from the original on 2019-08-09. Retrieved 2019-08-09. 

Àwọn Ìtàkùn ìjásóde àtúnṣe

Àdàkọ:Authority control