Zainab Bage Abubakar jẹ́ Adájọ́ ní Ilé-ẹjọ́ gíga ti ìjọba àpapọ̀ ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Wọ́n bí i ní ọjọ́ ọ̀kàn-dín-lógún oṣù kọkànlá ọdún 1964 ní Zuru ní ìlú Kebbi. [1]

Àwọn Ìtọ́ka Sí àtúnṣe

  1. "ABUBAKAR, Zainab Bage". Biographical Legacy and Research Foundation. 2020-01-06. Retrieved 2023-03-12.