Gloria Gaynor(orúkọ àbísọ rẹ̀ ni Gloria Fowles; tí a sì bí ní ọjọ́ keje oṣù kẹsàn ọdun 1943[1][2][3]) jẹ́ akorin ará Amẹ́ríkà tó gbajúmọ̀ fún àwọn orin disco rẹ̀; "I Will Survive", "Never Can Say Goodbye", "Let Me Know (I Have a Right)" àti "I Am What I Am".[4][5]

Gloria Gaynor
Gaynor in 2012
Gaynor in 2012
Background information
Orúkọ àbísọGloria Fowles
Ọjọ́ìbíOṣù Kẹ̀sán 7, 1943 (1943-09-07) (ọmọ ọdún 80)
Newark, New Jersey, U.S.
Irú orin
Occupation(s)
  • Singer
  • songwriter
Years active1965–present
LabelsJocida (1965)
MGM (1965–76)
Polydor (1976–83)
Chrysalis (1984–85)
Stylus (1986–88)
Hot Productions (1996–97)
Logic (2000–04)
Radikal (2005–present)
Associated actsSoul Satisfiers, Marvin Gaye, Luther Vandross
Websitegloriagaynor.com

Ìpìlẹ̀ ayé rẹ̀ àtúnṣe

A bí Gaynor sínú ìdílé Daniel Fowles àti Queenie Mae Proctor ní Newark, New Jersey,[6]. Ìyá bàbá tàbí màmá rẹ̀ ń gbẹ ní ẹgbẹ́ ilé tí wón bi sí, òun sì ló tọ́ Gaynor dàgbà.[7] "Orin ma ń wà ní ilé wa ní gbogbo ìgbà", Gaynor ko nínú ìwé ìtàn ayé rẹ̀; I Will Survive.

Ayé rẹ̀ àtúnṣe

Gaynor fẹ́ Linwood Simon ní ọdun 1979. Àwọn méjèjì kọ ara wọn sílè ní ọdun 2005.[8] Wọn kò bí ọmọ kọkan. Gẹ́gẹ́ bí Gaynor ṣe sọ, bí ó tilè jẹ́ wípé ó fẹ́ bí ọmọ, Linwood kò fẹ́ ọmọ.[9]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Newark Public Schools Historical Preservation Committee" (PDF). 
  2. Betts, Stephen L. (June 14, 2019) "Gloria Gaynor Preaches Survival on Inspiring New Gospel Album" Rolling Stone. Retrieved March 12, 2020.
  3. Maye, Warren L. (2019). "You Will Survive" Archived June 25, 2021, at the Wayback Machine.. SAConnects. Retrieved March 24, 2020.
  4. Gaynor, Gloria (April 10, 2000). I Will Survive: The Boo. St. Martin's Press. ISBN 0312300123. 
  5. Gaynor, Gloria (2000). I Will Survive: The Book. Unknown: St. Martin's Press. ISBN 0312300123. 
  6. Rosenfeld, Stacey (March 16, 2012). "Gaynor recalls how she 'survived' her lifestyle". Cliffside Park Citizen. https://www.newspapers.com/image/497909018. 
  7. Blanz, Sharla (December 19, 2007). ""I Will Survive" singer Gloria Gaynor graduated from Southside High School in Newark". Njmonthly.com 1961. Archived from the original on July 2, 2012. Retrieved December 27, 2012.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  8. Maslow, Nick. "Gloria Gaynor Is 'Back on Top' as She Releases Her First Gospel Album: This 'Is My Testimony'". People. https://www.yahoo.com/entertainment/gloria-gaynor-back-top-she-212744127.html?guccounter=1&guce_referrer=aHR0cHM6Ly93d3cuZ29vZ2xlLmNvbS91cmw_c2E9dCZyY3Q9aiZxPSZlc3JjPXMmc291cmNlPXdlYiZjZD0mdmVkPTJhaFVLRXdpVzhvUGN4NURzQWhWUS1hUUtIZG5NQVk4UUZqQVVlZ1FJQ0JBQiZ1cmw9aHR0cHMlM0ElMkYlMkZ3d3cueWFob28uY29tJTJGZW50ZXJ0YWlubWVudCUyRmdsb3JpYS1nYXlub3ItYmFjay10b3Atc2hlLTIxMjc0NDEyNy5odG1sJnVzZz1BT3ZWYXczOVl3YldoaFY4bmdJd2U1RzI0Umwz&guce_referrer_sig=AQAAALTT1wyrwbqK-X337BVCuUsvdImK67cpa6y0hUywS97kOtGf5Kj49fe3N-wf-fbOMDrQZ1dJWW3tX1066sm_kR-GbOju9HRGPF3KVQ0J1Xz6l2wGI5ywcy-i3q7VGys3mUMc4WN3J7JXLarxxSqKN506NObE1A7gkpk5DTs_Ej6m. 
  9. "Gloria Gaynor 'The Holy Spirit grabbed me by the collar in 1985'". The Guardian. July 6, 2019. Retrieved July 6, 2019.