“Omo“Ọmọ ti yóò j’asàmúj’aṣàmú, kékeré ló ti ńjenuńjẹnu sámúsámúṣámúṣámú lolọ.” Owe àwonàwọn àgbà yìí ló bá eniẹni tí ó kokọ ìwé yìí mu ògbéniọ̀gbẹ́ni OlátúbòsúnỌlátúbọ̀sún OládàpòỌládàpọ̀, nitori àkókò ti o ńkékòóńkẹ́kọ̀ọ́ ni ilé-ìwé àwonàwọn olùkóolùkọ́ ti Lúkù MimóMimọ́ ni ó kokọ ìwé yìí, nílùú Ìbàdàn.
Lákòókò yìí, mo ni ànfàní àti jéjẹ́ olùkóoolùkọ́ọ rèrẹ̀ nínú èkaẹ̀ka èkóẹ̀kọ́ Yorùbá, àti láti tún jéjẹ́ alábòjútó EgbéẸgbẹ́ ÌjìnlèÌjìnlẹ̀ Yorùbá ti KóléèjìKọ́lẹ́ẹ̀jì náà. LónàLọ́nà méjèèji yii ni ÒgbéniỌ̀gbẹ́ni OládàpòỌládàpọ̀ ti fi ara rèrẹ̀ hàn bii akoniakọni nínú èdèe Yorùbá. dé ibi pé ni odúnọdún ketakẹta rèrẹ̀ ni KóléèjìKọ́lẹ́ẹ̀jì, òun ni a fi jejẹ alága EgbéẸgbẹ́ ÌjinlèÌjinlẹ̀ Yorùbá ti KóléèjìKọ́lẹ́ẹ̀jì náà.
Nígbà tí ó sì dip é ki á máa wá eré ti egbéẹgbẹ́ yóò seṣe ní odúnọdún 1967, eré tirètirẹ̀ yii ni a yàn pé ó gbayì jù nínú gbogbo àwonàwọn eré ti a yèwòyẹ̀wò nígbà náà. ÀwonÀwọn ti ó wo eré náà nígbà ti àwonàwọn omoọmọ egbéẹgbẹ́ seṣe é ni GbòngànGbọ̀ngàn SèntínárìSẹ̀ntínárì ní Aké, AbéòkútàAbẹ́òkútà àti ni GbòngànGbọ̀ngàn ÀpèjoÀpèjọ ti Ilé-EkóẸkọ́ giga tí ìlú Ayétòrò ni, “àrímá -leèloleèlọ àwò-padà-séhin”sẹ́hin” ni eré náà í-seṣe. Eyi ló fún mi ni ìdùnnú láti lè kokọ òròọ̀rọ̀ àsosiwájúàsọsiwájú yìí lórí ìwé ÒGÚN LÁKÁAYÉ. Eré náà kókọ́ ènìyàn ni ògidìi Yorùbá. o fi orisirisIoriṣiriṣI àsààṣà Yorùbá hàn; ju gbogbo rèrẹ̀ lolọ, ó kókọ́ ènìyàn lógbónlọ́gbọ́n lórísirísilóríṣiríṣi ònàọ̀nà.
* OlatunbosunỌlatunbọsun OladapoỌladapọ (1983) Ògún Lákaayé Ibadan; Onibonoje Press and Book Industries (NIG) LTD. Ojú-iwé 138.