David Lyon (olóṣèlú): Ìyàtọ̀ láàrin àwọn àtúnyẹ̀wò

Content deleted Content added
Àwọn àlẹ̀mọ́: Àtúnṣe ojú fóónù Àtúnṣe ojú fóónù
Àwọn àlẹ̀mọ́: Àtúnṣe ojú fóónù Àtúnṣe ojú fóónù
Ìlà 4:
 
David Lyon Perewonrimi jẹ́ olùdarí àti Aláṣẹ ilé-iṣẹ́ àdáni àbó, Darlon Security and Guard, ní ìpínlẹ̀ Bayelsa. Ó jẹ́ ọmọ bíbí ẹbí Olodiana ni ìjọba ìbílẹ̀ Southern Ijaw ni ìpínlẹ̀ Bayelsa. Ó jẹ́ gbajúmọ̀ olówó àti olùṣowò, ṣùgbọ́n wọn kò fi bẹ́ẹ̀ mọ̀ ọ́n lágbo òṣèlú. Lọ́dún 2011 ni ó kọ́kọ́ díje dupò fún ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin Ìpínlẹ̀ Bayelsa ní ẹkùn Southern Ijaw Constituency IV lábẹ́ ẹgbẹ́ òṣèlú People’s Democratic Party, ṣùgbọ́n kò wọlé
Lẹ́yìn náà, ó dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress lọ́dún 2015.in 2011. Lọ́dún 2019, ẹgbẹ́ APC fà á kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bí adíje dupó fún gómìnà ìpínlẹ̀ Bayelsa. Ó sì borí nínú ìdìbò tó wáyé ní ọjọ́ kẹrìndínlógún oṣù kọkànlá ọdún 2019. Àjò elétò ìdìbò orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Independent National Electoral Commission, INEC, rẹ̀ lọ́jọ́ kejidinlogun oṣù kọkànlá ọdún 2019 pé òun ló wọlé. Ó wọlé pẹ̀lú àmín ìbò 352,552, akẹgbẹ́ rẹ̀ tí ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní àmìn ìbò 143,172.<ref name="Channels Television 2019">{{cite web | title=INEC Declares APC’s David Lyon Winner Of Bayelsa Governorship Election | website=Channels Television | date=2019-11-18 | url=https://www.channelstv.com/2019/11/18/breaking-inec-declares-apcs-david-lyon-winner-of-bayelsa-governorship-election/ | access-date=2019-11-18}}</ref> David Lyon ni Gómìnà àkọ́kọ́ nínú ẹgbẹ́-òṣèlú alátakò tí yóò jẹ gómìnà ní ìpínlẹ̀ Bayelsa, ẹgbẹ́ òṣèlú PDP ní ó tí ń wọlé gẹ́gẹ́ bíi gómìnà ìpínlẹ̀ náà láti ọdún 1999 tí òṣèlú àwarawa ti fẹsẹ̀ múlẹ̀ padà lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.