Bimbo Ademoye: Ìyàtọ̀ láàrin àwọn àtúnyẹ̀wò

Content deleted Content added
→‎Iṣẹ́: àfikún ìtọ́kasí
Ìlà 2:
{{Infobox person|image=|caption=}}
'''Bimbo Ademoye''' jẹ́ òṣèré ọmọ Nàìjíríà. Ní ọdún 2018, a yán fún òṣèré tí ó dára jùlọ nínú eré ìpanilẹ́rìn-ín / TV Jara ní ọ̀dọ̀ Àwọn Àṣàyàn Áfíríkà fún ipa rè nínu fíìmù ''Backup Wife'' (2017). Ó tún ńṣe ìràwọ̀ ROK TV, ìkànnì 329.<ref>https://www.thisdaylive.com/index.php/2019/02/09/bimbo-ademoye-marks-birthday-in-style/</ref>
== Ìbẹ̀rẹ̀ Ìgbésí ayé ìbẹ̀rẹ̀ àti ẹkọ rẹ̀ ==
A bí Ademoye ní Ọjọ́ Kẹrin, Oṣù Kẹrin , ọdún 1991, ní [[Èkó|Lagos]], gúúsù ìwọ̀ òrùn [[Nàìjíríà]] . Ó gba ẹ̀kọ́ ilé-ìwé gíga rẹ̀ láti Ile-iwe Mayflower àti pé ó jẹ́ alumna ti [[Yunifásitì Covenant|Ile-iwe Covenant]] níbití ó tí kẹ́kọ̀ọ́ Ìṣàkóso ìṣòwò . Nínu ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nu pẹ̀lú ìwé ìròyìn ''The Punch'', ó sọ pé bàbá nìkan ni ó ṣe àtìleyín fún iṣẹ́ tí ó yànláàyò<ref>https://punchng.com/my-dad-took-me-to-my-first-audition-bimbo-ademoye/</ref> .<ref>https://guardian.ng/life/complete-list-of-winners-for-the-2018-amvca/</ref><ref>http://www.ghafla.com/ng/actress-bimbo-ademoye-celebrates-her-birthday-with-stunning-photos/</ref>
 
== Iṣẹ́ ==
Nínu ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò pẹ̀lú ìwé ìròyìn ''Daily Independent'', ó sọ pé iṣẹ́ òṣèré rẹ̀ bẹ̀rẹ̀ ní ọdún 2014 nígbàtí wọ́n gbe sínu fíìmù kúkúrú ''Where Talent Lies'' fíìmù náà gba àwọn ìyìn láti Ayẹyẹ Fíìmù Káríayé Áfíríkà <ref>https://www.independent.ng/dont-enjoy-single/</ref>. Ó ṣe àpèjúwe Uduak Isong gẹ́gẹ́ bi olùkọ́ rẹ̀, ẹni tí ó ṣe ìrànlọ́wọ́ fun láti wọ ibi iṣẹ́ náà . Ní ọdún 2015, a gbé jáde ní fíìmù ẹ̀yà àkọ́kọ́ '' It's about your husband'' èyítí ó tún ṣe nípasẹ̀ Isong. Nínú àkójọ pọ̀ 2018 nípasẹ̀ ìwé ìròyìn ''Premium Times'', Ademoye jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn òṣèré márùn-ún tí o ní àsọtẹ́lẹ̀ láti ní iṣẹ́ àṣeyọrí ṣáájú òpin ọdún .