Sunday Ìgbòho: Ìyàtọ̀ láàrin àwọn àtúnyẹ̀wò
Content deleted Content added
Macdanpets (ọ̀rọ̀ | àfikún) New Page Àwọn àlẹ̀mọ́: Àtúnṣe ojú fóónù Àtúnṣe ojú fóónù Advanced mobile edit |
(Kò ní yàtọ̀)
|
Àtúnyẹ̀wò ní 14:20, 23 Oṣù Kínní 2021
Chief Sunday Ìgbòho tí orúkọ àbísọ rẹ̀ gan-an ń jẹ́ Sunday Adéníyì Adéyẹmọ (tí wọ́n bí lọ́jọ́ kẹwàá oṣù kẹwàá ọdún 1972 [1]) jẹ́ gbajúmọ̀ ajìjàǹgbara, olóṣèlú àti ajàfẹ́tọ̀ọ́ ọmọ ènìyàn ọmọ bíbí Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ ajìjàǹgbara fún ìdásílẹ̀ orílẹ̀-èdè Oòduà àti ìṣọ̀kan àwọn ọmọ Yorùbá káàkiri Nàìjíríà.[2] Òun ni alága àti olùdásílẹ̀ ilé-iṣẹ́ Adeson International Business Concept Ltd, bẹ́ẹ̀ náà Wọ́n fi òye Akọni Oòduà ilẹ̀ Yorùbá dáa lọ́lá.[3] Sunday di gbajúmọ̀ ìlúmọ̀ọ́ká lórí ìkànnì abánidọ́rẹ̀ẹ́ lósù kìíní ọdún 2021 nígbà tí ó àwọn darandaran Fúlàní ní gbèǹdeke ọjọ́ méje láti kúrò nílẹ̀ Ìbàràpá nítorí ìpakúpa tí wọ́n fura pé àwọn Fúlàní wọ̀nyí ló pa Ọ̀mọ̀wé Abọ́rọ̀dé.[4][5]
Chief Sunday Igboho | |
---|---|
Ọjọ́ìbí | Sunday Adeniyi Adeyemo 10 Oṣù Kẹ̀wá 1972 Igboho town, Oke ogun, Oyo state |
Iṣẹ́ | Human rights activist, politician |
Àwọn ìtọ́kasí
- ↑ "Seven things to know about Sunday Igboho". Latest Nigeria News, Nigerian Newspapers, Politics (in Èdè Latini). 2021-01-23. Retrieved 2021-01-23.
- ↑ Nenge, Katrine (2018-10-16). "Handsome and successful: The story of Sunday Igboho’s". Legit.ng - Nigeria news. (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-01-21.
- ↑ Alao, Moses. "2019: I Inherited Powers To Command Guns From My Father —Sunday Igboho". tribuneonlineng.com. Retrieved 2021-01-21. Unknown parameter
|url-status=
ignored (help) - ↑ "INSECURITY: Why Fulani herders must leave Oyo - Igboho". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-01-19. Retrieved 2021-01-21.
- ↑ "Nothing must happen to Igboho, Ibarapa Youths warn FG, Oyo govt". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-01-20. Retrieved 2021-01-21.