Àdàkọ:Àyokà Ose/18: Ìyàtọ̀ láàrin àwọn àtúnyẹ̀wò

Content deleted Content added
(Kò ní yàtọ̀)

Àtúnyẹ̀wò ní 13:39, 3 Oṣù Kàrún 2021

Obafemi Awolowo, olórí Agbègbè Apáìwọ̀òrùn Nàìjíríà
Obafemi Awolowo, olórí Agbègbè Apáìwọ̀òrùn Nàìjíríà

Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ (6 oṣù kẹta ọdún 1909 - 9 oṣù karún ọdún 1987), jẹ́ olósèlú ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà láti ẹ̀yà Yorùbá. Awólọ̀wọ̀ jẹ́ olórí fún àwon ọmọ ilẹ̀ Yorùbá àti ọ̀kan nínú àwọn olóṣèlú pàtàkì ni orílẹ̀ èdè Nàìjíríà. A bí ni ọjọ́ kẹfà osù kẹta ọdún 1909 ni Ìkẹ́nnẹ́ tó wà ní ìpínlẹ̀ Ogun lóòní. Omo àgbẹ̀ tí ó fi iṣẹ́ àti ògùn ìsẹ́ ṣọ ara rẹ̀ di ọ̀mọ̀wé, Awólọ́wọ̀ lọ ilé ẹ̀kọ́ Anglican àti Methodìst ni Ikénne àti ni Baptist Boys' High School ni Abéòkúta. Lèyìn rè ó ló sí Wesley College ni Ibàdàn tí ó fi ìgbà kan jé olùìlú Agbègbè Apáìwọ̀òrùn Nàìjíríà láti ba di Olùko. Ní ọdún 1934 , ó di olùtajà àti oníròyìn. O se olùdarí àti alákóso Egbé Olùtajà Awon Omo Nàìjíríà (Nigerian Produce Traders Association) àti àkòwé gbogbogbo Egbé Awon Awako Igb'eru Omo Ilè Nàìjíríà (Nigerian Motor Transport Union).

(ìtẹ̀síwájú...)