Ìwé Nehemáyà jẹ́ ìwé Bíbélì Mímọ́ tó sọ̀rọ̀ nípa àkókò kan nínú ìtàn àwọn Júù, ìyẹn bí i ìránṣẹ́ Ọlọ́run Nehemáyà ṣe padà sí Jerúsálẹ́mù láti bẹ̀rẹ̀ àti dárí kíkọ́ ilẹ̀ wọn àti títún ìgbàgbọ́ wọn tò, nítorí wọ́n ṣẹ̀ṣẹ̀ bọ́ nínú ìgbèkùn Bábílónì ní.

Kíkọ́ odi Jerúsálẹ́mù

Itokasi àtúnṣe