Ruth Kadiri

(Àtúnjúwe láti Ruth Kádírì)

Ruth Kádírì jẹ́ òṣèré orí-ìtàgé, olùkọ fọ́rán àwòkà eré ìtàgé àti olùgbéré jáde ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Ruth Kadiri in the Nigerian film "First Class" in 2016
Ruth Kádírì
Ọjọ́ìbíọjọ́ Kẹrìlélógún oṣù Kẹta ọdun 1988
ìlú Benin
Ọmọ orílẹ̀-èdèNàìjíríà
Ẹ̀kọ́Mass communications,Yunifásítì ìlú Èkó
Iléẹ̀kọ́ gígaYunifásítì ìlú Èkó
Iṣẹ́òṣèré orí-ìtàgé

Ìbẹ̀rẹ̀ Ayé rẹ̀ àtúnṣe

Wọ́n bí Ruth ní ọjọ́ Kẹrìlélógún oṣù Kẹta ọdun 1988 ní ìlú Benin tí ó jẹ́ olú-ìlú fún Ìpínlẹ̀ Ẹdó, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó lọ sí Ilé ẹ̀kọ́ gbogbonìṣe ti Yábàá, tí ó kẹ́kọ̀ọ́ nípa Business Administration, bákan náà ni ó kẹ́kọ̀ọ́ jáde gboyè àkọ́kọ́ ní Yunifásítì ìlú Èkó nínú ìmọ̀ ìbá ọ̀pọ̀ ènìyàn sọ̀rọ̀ (Mass communications) .[1]

Àwọn Ìtọ́ka sí àtúnṣe