Àdúrà Olúwa jẹ́ àdúrà tí àwọn Ẹlẹ́sìn ọmọ lẹ́yìn Jésù Kírísítì kọ́ àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ nínú Bíbélì, nínú ìwé Mátíù orí kẹfà, ẹsẹ kẹsàn-án títí dé kẹtàlá. Ó jẹ́ àdúrà tí àwọn kírísítẹ́nì máa ń gba pẹ̀lú Ọ̀wọ̀ níbikíbi tí wọ́n bá ti ń gbà á. [1] [2] [3]

Àdúrà Olúwa gẹ́gẹ́ bí ó ti wà nínú Bíbélì àtúnṣe

6:9 Nitorina bayi ni ki ẹnyin mã gbadura: Bàbá wa tí ḿ bẹ ní ọ̀run; Kí á bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ.

6:10 Kí ìjọba rẹ dé; Ìfẹ́ tìrẹ ni kí a ṣe ní ayé, bi ti ọrùn.

6:11 Fún wa ní oúnjẹ oòjọ́ wa lónìí

6:12 Dárí gbèsè wa jìn wá, bí àwa ti ń darijì àwọn onígbèsè wa.

6:13 Má si fà wá sínú ìdánwò, ṣùgbọ́n gbà wá lọ́wọ́ bìlísì. Nítorí ìjọba ni tìrẹ, àti agbára, àti ògo, láyéláyé. Àmín.

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Buls Sermon Notes Easter V". Christian.net. Retrieved 2020-01-07. 
  2. "Catechism of the Catholic Church - The summary of the whole Gospel". Vatican. Retrieved 2020-01-07. 
  3. Farmer, W.R. (1994). The Gospel of Jesus: The Pastoral Relevance of the Synoptic Problem. Westminster/John Knox Press. p. 49. ISBN 978-0-664-25514-5. https://books.google.com/books?id=KkO4qzxHrsEC&pg=PA49. Retrieved 2020-01-07.