Abike Dabiri

Oníwé-Ìròyín

Abike Kafayat Olúwa Toyin Dabiri-Erewa jẹ́ òṣèlú àti ọmọ ẹgbẹ́ tẹ́lẹ̀ fún Nigeria Federal House of Representatives, òun sì ni aṣojú fún Ìlú Ìkoròdú tí Ìpínlẹ̀ Èkó níbẹ̀.[1][2] Òun ni alága tẹ́lẹ̀ fun ìgbìmò ìkéde àti media.[3] Òun sì ní alága tẹ́lẹ̀ fún ìgbìmò Diaspora Affairs.[4] Ní ọdún 2015, ó di oluranlọwọ pàtàkì àgbà fún Olórí orílẹ̀ èdè Nàìjíríà, Muhammadu Buhari lórí ọ̀rọ̀ àjèjì. Ní oṣù kọkànlá ọdún 2018, ó di alákóso fún àwọn ọmọ Nàìjíríà tí ó wà ní Diaspora Commission.[5][6][7][8][9][10] Ó jẹ́ olùfọwọ́sí fún Together Nigeria, tí ó jẹ́ ètò tí wọn gbé kalẹ̀ láti lè si ṣẹ́ kí Buhari lé wọlé gẹ́gẹ́ bíi olórí orílẹ̀ èdè ni ọdún 2019.[11] O gboyè nínú èdè gẹ̀ẹ́sì ni ilé ẹ̀kọ́ gíga tí University of Ifè. O lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga tí University of Lagos níbi tí ó tí gboyè  masters nínú Mass Communication.[12]

Abike Dabiri-Erewa
Abike Dabiri níbi àgbéjáde kan
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
2016-2019
Chairman/CEO of Nigerian Diaspora Commission
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíJos, Plateau State
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAll Progressives Congress
OccupationPublic servant

Iṣẹ́ àtúnṣe

Dabiri ṣi ṣé pẹ̀lú Nigerian Television Authority (NTA) fún ọdún mẹ́ẹ̀dógún, ó sì ṣe atọkun fún àwọn ètò ìròyìn pàápàá jù lọ ní pa ìṣẹ́. Ó fi ise agbóhùnsáfẹ́fẹ́ sílè fún òṣèlú. Òun ni alága fún ìgbìmò media ni Federal House of Representatives láti ọdún 2007.[2][13]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "biography". abikedabiri.com. Archived from the original on 2009-03-27. Retrieved 2009-12-20.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. 2.0 2.1 "About – Hon Abike Dabiri-Erewa". Retrieved 13 September 2019. 
  3. Luke Onyekakeyah (9 August 2013). The Crawling Giant. AuthorHouse. pp. 169–. ISBN 978-1-4772-7779-9. https://books.google.com/books?id=cet7AAAAQBAJ&pg=PA169. 
  4. Abiodun Adelaja and Adekunle Adesuj (December 18, 2009). "Nigeria: Death of Student - Dabiri-Erewa Slams Nigerian Envoy to Cyprus". Daily Champion. http://allafrica.com/stories/200912180375.html. 
  5. "Buhari gives Abike Dabiri new role" (in en-GB). Premium Times Nigeria. 2018-11-06. https://www.premiumtimesng.com/news/more-news/294339-buhari-gives-abike-dabiri-new-role.html. 
  6. guardian.ng https://guardian.ng/news/buhari-appoints-abike-dabiri-erewa-as-national-diaspora-commission-chairman/. Retrieved 2020-05-01.  Missing or empty |title= (help)
  7. "Buhari appoints Abike Dabiri-Erewa as diaspora commission chairman". TheCable (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-11-06. Retrieved 2020-05-01. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  8. Iroanusi, QueenEsther (2019-05-09). "Senate confirms Abike Dabiri-Erewa as head of Nigerian Diaspora Commission - Premium Times Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-01. 
  9. "Senate confirms Dabiri-Erewa as chairman, Nigerians Diaspora Commission". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-05-09. Retrieved 2020-05-01. 
  10. Published. "Senate confirms Abike Dabiri-Erewa as Chairman/CEO of Nigerian Diaspora Commission". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-04-21. 
  11. The Eagle Online (21 December 2018). "Why I am Supporting Together Nigeria, by Abike Dabiri-Erewa". The Eagle Online. The Eagle Online. https://theeagleonline.com.ng/why-i-am-supporting-together-nigeria-by-abike-dabiri-erewa/. Retrieved 11 March 2019. 
  12. "Abike Kafayat Oluwatoyin Dabiri-Erewa,Role Model,Senior Special Assistant, Politician". Retrieved 13 September 2019. 
  13. "Nigerian Press Council Bill: Reps member appeals for understanding". Retrieved 13 September 2019.