Adéwálé Ẹlẹ́ṣọ̀ọ́

Adéwálé Ẹlẹ́ṣọ̀ọ́ tí orúkọ àbísọ rẹ̀ gangan jẹ́ Adéwálé Adéoyè tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kìíní ọdún 1959[1] jẹ́ gbajúmọ̀ aláwàdà àti ọ̀ṣẹ̀rè sinimá-àgbéléwò lédè Yorùbá ọmọ bíbí ìlú Ìkirun ní ní ìjọba ìbílẹ̀ Ìfẹ́lódùn ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀ṣun lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni eré sinimá-àgbéléwò tí ó ti kópa. Ó ti tó ọdún mẹ́rìndínlógójì (36) tí Adéwálé Ẹlẹ́ṣọ̀ọ́ ti bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ sinimá-àgbéléwò. [2]

Bí Adéwálé Ẹlẹ́ṣọ̀ọ́ ṣe jẹ́ gbajúmọ̀ ọ̀ṣẹ̀rè, bẹ́ẹ̀ náà ló ń ṣe òṣèlú. [3]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Adeoye Adewale (Elesho) (Actor) - Age and Movies". INSIDENOLLY. 1959-01-10. Archived from the original on 2020-07-02. Retrieved 2020-07-02. 
  2. "Yoruba actor, Elesho, celebrates 30 years on stage". Premium Times Nigeria. 2014-03-01. Retrieved 2020-07-02. 
  3. "'What I will miss about my mom' – Actor Elesho". Encomium Magazine. 2015-07-24. Retrieved 2020-07-02.