Adaora Onyechere jẹ́ oniroyin, oníṣòwò, akéwì àti onkọ̀we ni ìlẹ̀ Nàìjíríà. Òun sì ní atọkun ètò tẹ́lẹ̀ fún ètò Kakaaki, lórí Africa Independent Television.[1] Òun sì ní atọkun ètò Talk 2 Adaora lórí Kiss Fm ni gbogbo ọjọ́ ìṣẹ́gun ní ago mẹrin ìrọ̀lẹ́. Òun ni oludasile ẹgbẹ́ Women Enabling Women Everywher (WEWE).[2] Òun náà ni olùdarí signature heels media.

Adaora Onyechere
CEO Wewe Network Afrique
CEO Wewe Network Afrique
Ọjọ́ìbíOkigwe, Imo State
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iléẹ̀kọ́ gíga
Iṣẹ́
  • Entrepreneur
  • Broadcaster Journalist
  • Philanthropist
  • motivational speaker
  • Author
Gbajúmọ̀ fúnco-anchor of Kakaaki, a daily talk show on Africa Independent Television
Title
  • Executive Director of Yellow Jerrycan Save A Child Foundation.
  • CEO of Signature heels
  • CEO of WEWE Network Afrique
  • Host of Talk2Adaora on kiss 99.9 FM

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀ àtúnṣe

Wọn bíi sì ilẹ̀ Nàìjíríà, ó sì jẹ ọmọ ìlú Okigwe ni ìpínlè Imo. Adaora jẹ́ àkọ́bí láàrín àwọn ọmọ mẹ́fà tí àwọn òbí rẹ bí.[3] Adaora lọ sí ilé ẹ̀kọ́ Starland Private School ni ìpínlè èkó fún ẹ̀kọ́ ìbéèrè. Ó lọ sí Owerri Girls Secondary School. Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga tí Coventry University níbi tí ó tí ká ìwé imọ òfin. Ó tún lọ sí London Metropolitan University àti Oxford Brooks University.[4]

Ìṣe àtúnṣe

Kí ó tó padà sí ilé Nàìjíríà ni ọdún 2009, Adaora sisẹ́ fún World view magazine ni ilé United Kingdom.[5] Adaora ṣe agbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún Coventry Student Radio ni ìgbà tí ó sì jẹ akẹ́kọ̀ọ́ ni ilé ẹ̀kọ́ náà kì ó tó padà lọ ṣíṣe ni Channel 4 London. Ó sisẹ́ fun Ben Television ni London gẹ́gẹ́ bíi alatunse àti olootu ètò African Film Review. O ṣiṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún Confluence Cable Network Limited ni ìpínlè Kogi, Federal Radio Corporation of Nigeria, Vision Fm àti DAAR communications.[6][7] Ó dára pọ̀ òṣèlú ó sì dù òye ọmọ ẹgbẹ́ igbimo asofin tí ipinle Imo ṣùgbọ́n kò wọlé.[8][9] Adaora jẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún ètò Talk2Adaora lórí Kiss 99.9 Fm. Adaora jẹ́ onkọ̀we, ó sì tí kọ àwọn iwe bíi Poetry for life, Black Girl with a white heart, Women in the world, Arise àti Fear.[10]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Kakaaki. "Adaora Onyechere". Africa Independent Television. Retrieved 15 August 2015. 
  2. "WEWE NETWORK AFRIQUE". Archived from the original on 1 November 2020. Retrieved 9 April 2020. 
  3. Yomi Odunuga, Grace Obike (16 May 2015). "Life as a single mother-TV gal Adaora Onyechere". The Nation Newspaper. Retrieved 15 August 2015. 
  4. Fwangshak Guyit, Naomi Tetteh (29 November 2013). ""I had a speech defect growing up" – AIT’S Ada Onyechere". Garki Gazette. Archived from the original on 5 March 2016. https://web.archive.org/web/20160305144235/http://www.garkigazetteonline.com/content.php?cat_id=5465456576&c_id=30783389&fb_comment_id=388870104580214_2079274#f17bc693a8a9db. Retrieved 15 August 2015. 
  5. "Adaora Onyechere.". Nigerian Biography. Retrieved 15 August 2015. 
  6. "‘Kaakaki’ host Adaora Onyechere leaves AIT to Pursue a career in politics". PER SECOND NEWS. 28 August 2018. 
  7. ENWONGO, ATING (28 August 2018). "Television Queen, Adaora Onyechere Bows Out Of AIT". The Whistler NG. 
  8. Erunke, Joseph (6 October 2018). "Imo 2019: I'll redesign South East educational curriculum-Onyechere". Vanguard News Nigeria. 
  9. "Gov. Ihedioha makes more appointments". Daily Post. Retrieved 31 July 2019. 
  10. "LAUNCH OF ADAORA ONYECHERE’S ‘CHANGE SMITTEN’ IN ABUJA". Photo News. Archived from the original on 2 April 2015. Retrieved 16 March 2015.