Adebimpe Oyebade (tí a bí ní 23 oṣù kẹta 1992) tí a mọ̀ sí Mo Bimpe jẹ́ òṣèré fíìmù Nàìjíríà tí a mọ̀ fún gbígba àmì-ẹ̀yẹ ti ọdún 2018 ní City People Entertainment Awards gẹ́gẹ́ bíi òṣèré titun titun ti ọdún náà.

Adebimpe Oyebade
Ọjọ́ìbí23 Oṣù Kẹta 1992 (1992-03-23) (ọmọ ọdún 32)
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànMo Bimpe[1]
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigeria
Iléẹ̀kọ́ gígaEkiti State University
Iṣẹ́Film actress
Olólùfẹ́
Lateef Adedimeji (m. 2021)

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Bassey, Ekaete (July 14, 2022). "Why Fabiyi and I are ‘enemies’ – Mo Bimpe The Nation Newspaper". The Nation Newspaper. Retrieved July 22, 2022.