Angela Olufunmilayo Emuwa jẹ́ adarí àwọn oníròyìn ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ alága Punch Media Foundation, tí àwọn ìgbìmọ̀ Punch Nigeria Limited yàn ní ọdún 2018, lẹ́yìn ikú ẹ̀gbọ́n rẹ̀ Gbadebowale Wayne Aboderin, ní ọjọ́ ọgbọ̀n oṣù karùn-ún ọdún 2018.[1] Kí wọ́n tó yàn án sípò gẹ́gẹ́ bí alága, ó ti dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ náà ní ọdún 1994, ó sì ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi olùdarí tí kì í ṣe aláṣẹ ilé-iṣẹ́ náà. 

Angela Emuwa
Orúkọ àbísọOlufunmilayo
Ààyè lọ́wọ́Active
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànOlufunmilayo
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Ẹ̀kọ́ESUT Business School
Iṣẹ́Media executive, Journalist
OrganizationPunch Media Foundation
PredecessorGbadebowale Aboderin
Parent(s)

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Our Board – PUNCH Media Foundation" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved November 13, 2021.