Angelica Nwandu (tí wọ́n bí ní May 10, 1990)[1][2] ni olùdásílẹ̀ the Shade Room (TSR), èyí tó jẹ́ ilé-iṣẹ́ orí ẹ̀rọ-ayélujára tó níṣe pẹ̀lú ṣíṣe òfófó àwọn gbajúmọ̀. Iye àwọn ènìyàn tó ń wo ètò yìí ń lọ bí i 20 million.[3][4] Ní ọdún 2016,The New York Times to the Shade Room sábẹ́ àwọn ètò tó gbajúmọl jù lọ ní orí ẹ̀rọ-ayélujára.[5]

Angelica Nwandu
Nwandu in 2020
Ọjọ́ìbí10 Oṣù Kàrún 1990 (1990-05-10) (ọmọ ọdún 33)
Los Angeles, California
Iṣẹ́Online Black celebrity gossip
Ìgbà iṣẹ́2014-present
Gbajúmọ̀ fúnFounder, the Shade Room

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Abumere, Princess (May 10, 2017). "5 things you should know about the Shade Room founder". pulse.ng. Retrieved June 4, 2020.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "Today is my bday". www.instagram.com. Retrieved 2023-07-22. 
  3. "Live Session With Angelica Nwandu CEO and Founder of The Shade Room". The Hype Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-05-16. 
  4. Davis, Allison P. (2019-10-21). "How I Get It Done: Angelica Nwandu, Founder and CEO of The Shade Room". The Cut (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-07-22. 
  5. Wortham, Jenna (April 14, 2015). "Instagram's TMZ". The New York Times.