Anthonia Adenike Adeniji

Anthonia Adenike Adeniji (tí a bí ní ọjọ́ karúndínlọ́gbọ̀n oṣù keje ọdún 1971) jẹ́ ọ̀mọ̀wé àti ọ̀jọ̀gbọ́n ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ igbákejì ọ̀jọ̀gbọ́n[1] nínú ìmò dídarí ọkọ òwò ní Yunifásítì Covenant, Ìpínlẹ̀ Ogun, Nàìjíríà.

Anthonia Adenike Adeniji
Born25 Oṣù Kẹ̀sán 1971 (1971-09-25) (ọmọ ọdún 52)
Ota, Ogun, Nàìjíríà
InstitutionsYunifásítì ti Covenant
Alma materOlabisi Onabanjo University (B.Sc.)
Obafemi Awolowo University (M.B.A.)
Covenant University (Ph.D.)

Ìpìlẹ̀ àti Ẹ̀kọ́ rẹ̀ àtúnṣe

Wọ́n bí Adeniji ní ọjọ́ karúndínlọ́gbọ̀n oṣù kẹsàn-án ọdún 1971, ní Ìlú Ota, ti ìpínlẹ̀ Ogun State. Ó parí ẹ̀kọ́ B.Sc. rẹ̀ nínú ìmọ̀ ìdarí ọkọ òwò ní ọdún 1995 ní Yunifásítì Olabisi Onabanjo. Ó gba àmì-ẹ̀yẹ Post Graduate Diploma in Financial Management (PGDFM) ní ọdún 1997 ní Yunifásítì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀ níbè ló tún ti gba àmì-ẹ̀yẹ M.B.A. ní ọdún 2000 kí ó tó gba àmì-ẹ̀yẹ P.H.D. ní Yunifásitì Covenant ní ọdún 2011.

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Dr. Anthonia Adenike Adeniji". Covenant University. Archived from the original on 24 November 2020. Retrieved 29 May 2020.