Dafidi Oluwafemi Adewunmi Abdulateef Fani-Kayode tí a bí ní ọjọ́ kẹ́rindínlógún oṣù kẹjọ, ọdún 1960 jẹ́ olóṣèlú ọmọ Nàìjíríà, òǹkọ̀wé àti agbẹjọ́rò. A bí Fani-Kayode ní ìlú Èkó, Nàìjíríà, ó sì di Olùrànlọ́wọ́ Àkànṣe fún Ọ̀rọ̀ Ìjọba fún Olusegun Obasanjo láti oṣù keje ọdún 2003 sí oṣù kẹfà ọdún 2006. A yàn án gẹ́gẹ́ bí Mínísítà fún Àṣà àti Ìrìn-àjò ti Orílẹ̀-èdè Olómìnira Àpapọ̀ Nàìjíríà láti ọjọ́ kejìlélógún oṣù kẹfà sí ọjọ́ keje oṣù kọkànlá ọdún 2006, àti Minísítà fún Iṣẹ́ Òfuurufú láti ọjọ́ keje oṣù kọkànlá ọdún 2006 sí ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù karùn-ún ọdún 2007.

Femi Fani-Kayode
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí
Femi Fani-Kayode

16 Oṣù Kẹ̀wá 1960 (1960-10-16) (ọmọ ọdún 64)
Lagos, Lagos State, Nigeria
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
ProfessionLawyer

Fani-Kayọde ni oludamoran pataki (lori oro nipa ara ilu) fun Áárẹ Oluṣẹgun Ọbasanjọ lati osu kejo odun 2003 titi di osu kefa odun 2006. A yan gegebi alamojuto oro to je mo Asa ati Igbafe ni orile-ede Naijiria lati ojo keji-le-logun osu kefa si ojo keje osu kokanla odun 2006 ati gegebi alamoju fun oro to je mo irina oju ofurufu lati ojo keje osu kokanla odun 2006 titi di ojo kokan-din-logbon osu karun odun 2007.[1][2][3][4][5][6][7][8]

Ìbẹ̀rè Ìgbé Ayé àti Ẹ̀kọ́

àtúnṣe

Bàbá tó bí bàbá bàbá rẹ̀, Àlúfà Èmánúẹ́lì Adédápọ̀ Káyọ̀dé, jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàíjíríà tí ó kọ́kọ́ lọ kà'wé ní Ìlú Ọba gb'oyè akọ́'ṣẹ́ mọ'ṣẹ́ láti ilé ẹ̀kọ yunifásitì ti Durham, leyin eyi ti o di alufa ni ijo Angilikan after which he became an Anglican priest. His grandfather, Victor Adedapo Kayode, studied law at Cambridge University and became a lawyer and a judge. His father Victor Babaremilekun Adetokunboh Fani-Kayode, who was also at Cambridge was a prominent lawyer and political figure in Nigeria in the 1950s and 1960s. He was Leader of the National Council of Nigeria and the Cameroons Opposition in the Western House of Assembly from 1960 to 1963, the Hon. Minister of Local Government and Chieftaincy Affairs and Deputy Premier of the Western Region of Nigeria from 1963 until 1966 and he successfully moved the motion for Nigeria's independence in 1958 in the Nigerian Parliament.[9][10]

References

àtúnṣe