Femi Otedola (ojobi 4 Osu kokanla odun 1962) je onisowo orile-ede Naijiria, oninuure, ati alaga tele fun Forte Oil PLC. Lówọ́lówó, Ó jé álágá Geregu Power PLC

Femi Otedola
Ọjọ́ìbí4 Oṣù Kọkànlá 1962 (1962-11-04) (ọmọ ọdún 61)
Ibadan, Oyo State, Nigeria
Ẹ̀kọ́Olivet Baptist High School
Obafemi Awolowo University
Iṣẹ́Businessman
Olólùfẹ́Nana Otedola
Àwọn ọmọ4, including Temiloluwa Elizabeth Otedola
Parent(s)Sir Michael Otedola

Igbesi aye ibere àtúnṣe

Wo bi Otedola ni ilu Ibadan, olu ilu ipinle Oyo, guusuiwoorun Naijiria, ninu idile Oloogbe Sir Michael Otedola, Gomina Ipinle Eko lati 1992 si 1993.[1]

Itokasi àtúnṣe

  1. "Ex-Lagos gov, Sir Michael Otedola, dies at 87". Vanguard News. 2014-05-05. Retrieved 2022-02-06.