Fenda Lawrence (1742[1] – lẹ́yìn 1780), jẹ́ olóko òwò ẹrú Áfíríkà tí ó ṣiṣẹ́ yìí ní Saloum, ìlú Kaur.

Fenda Lawrence
Ọjọ́ìbícirca 1742
Saloum
AláìsíAfter 1780
Iṣẹ́Slave trader

Ìtàn ayé rẹ̀ àtúnṣe

Fenda Lawrence gbé lẹ́gbẹ̀ẹ́ odò Gambia ní àwọn ọdún 1700s. Ní àdúgbò náà, ó jé òlùbádúna dúrà láàrin àwọn oníṣòwò Britain, France àti àwọn oníṣòwò Áfíríkà. Ó di ipò yìí mú lẹ́yìn ìgbà tí ó fẹ́ Òyìnbó kan. Lawrence ṣiṣẹ́ láti Saloum ìlú tí Kaur.[2] Ní ọdún 1772, Lawrence lọ sí Thirteen Colonies ti America láti ṣòwò.[3] Nígbà yìí, ó ti yapa láti ọ̀dọ̀ Oko òyìnbó tí ó fẹ́.[2]

Nígbà tí ó wọ ọkọ ojú New Britannia, Lawrence mú ẹrú márùn-ún pẹ̀lú ara rẹ̀. Ọkọ̀ náà déCharleston, South Carolina, lẹ́yìn ọjọ́ méjìdínlógójì tí ọ́ gbéra. Adarí ọkọ̀ náà, Stephen Deane, sì tẹ̀lé Lawrence lọ sí Georgia.[2]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Hassoum Ceesay: Gambian women: an introductory history. 1. Auflage. Fulladu Publishers, Gambia 2007
  2. 2.0 2.1 2.2 Akyeampong & Gates, Jr. 2012, p. 475.
  3. Holloway 2005, p. 49.