Grace Nortey (tí wọ́n bí ní ọjọ́ kìíní oṣù kejì ọdún 1937) jẹ́ òṣèrébìnrin ti orílẹ̀-èdè Ghana tó ti kópa nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ fíìmù àgbéléwò àti ti ẹ̀rọ amóhùnmáwòrán.[1] Ó ti kópa nínú fíìmù àgbéléwò, eré orí-ìtàgé àti eré-oníṣe lóríṣiríṣi fún àádọ́ta ọdún, tí ó sì tún jẹ́ ọ̀kan lára àwọn àgbà ọ̀jẹ̀ inú fíìmù àgbéléwò ti orílẹ̀-èdè Ghana. [2]

Grace Nortey
Ọjọ́ìbí1 Oṣù Kejì 1937 (1937-02-01) (ọmọ ọdún 87)
Ghana
Iṣẹ́Actress
Ìgbà iṣẹ́1970s–present
Àwọn ọmọ5

Ìgbésí ayé ara ẹni

àtúnṣe

Nortey bí ọmọ márùn-ún. Òun sì ni ìyá Sheila Nortey tí òun náà jẹ́ òṣèré.

Àtòjọ àwọn fíìmù rẹ̀

àtúnṣe

Àwọn fíìmù

àtúnṣe
Ọdún Fíìmù Ẹ̀dá-ìtàn Ọ̀rọ̀
1985 Nana Akoto
1992 The Other Side of the Rich Mrs. Ampofo
2006 Frozen Emotion Direct-to-video
2008 Before My Eyes Wummi Direct-to-video
2011 Sinking Sands Grandma
Ties That Bind Church Member
2015 Beasts of No Nation Old Witch Woman
2019 P over D Ayorkor
'95 Old Woman

Àtòjọ àwọn àmì-ẹ̀yẹ rẹ̀

àtúnṣe
  • Best Cameo Actress (Movie: "Adams Apple") - Ghana Movie Awards (2011[3])
  • Excellence in Arts - Glitz Women of the Year Honours (2016)
  • Lifetime Achievement Award - Black Star International Film Festival (BSIFF) Awards (2018)
  • Legendary Award for Outstanding Contributions: Ghana Actors Entertainment Award (GAEA) - (2020)
  • Outstanding Contribution to Women's Excellence in The Performing Arts - 3Music Awards Women's Brunch (2021)

Àwọn ìtọ́kasí

àtúnṣe
  1. "Glitz top 100 inspirational women – Page 100 – Glitz Africa Magazine" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-05-28. 
  2. "Grace Nortey Marks 87th Birthday". DailyGuide Network. 2024-02-05. Retrieved 2024-08-19. 
  3. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named :0