Kafilat Ọ̀gbàrá jẹ́ oníṣòwò àti òṣèlú ọmọ ẹgbẹ́ aṣojú-ṣòfin ẹ̀kẹwàá ọmọ orílẹ̀-èdè Nigeria House of Representatives.[1][2] Ó borí nínú ìdìbò lọ́dún 2023 nínú ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress pẹ̀lú iye ìbò 45,111, èyí ló fi borí àwọn alátakò rẹ̀, Florence Adepegba, tí ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú People’s Democratic party tí ó rí iye ìbò tí ó jẹ́ 28,964 àti Abdulwaheed Odunuga ti ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú New Nigeria People's Party tí ó rí ìbò 4152.[3]

Kafilat Ọ̀gbàrá
Member of the House of Representatives of Nigeria for Kosofe
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
June 2023
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí1972
Lagos
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
Ẹgbẹ́ olóṣèlúAPC
ẸbíAlhaji & Alhaja M. Ade Kasumo
ResidenceAbuja
Alma materUniversity of Lagos
Occupation
  • businesswoman
  • Legislature

Àwọn Ìtọ́kasí

àtúnṣe