Kofoworola Bucknor
Kofoworola Bucknor-Akerele (tí a bí ní ọjọ́ ọgbọ̀n, osù kẹrin, ọdún 1939) jẹ́ olósèlú àti igbákejì gómìnà Ipinle Eko nígbà kan rí.[1] Òun ni igbákejì gómìnà nígbà ìjọba gómìnà Bola Tinubu láàrin ọdún 1999 wọ ọdún 2003.[2]
Kofoworola Bucknor-Akerele | |
---|---|
11th Deputy Governor of Lagos State | |
In office 29 May 1999 – 29 May 2003 | |
Arọ́pò | Femi Pedro |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | 30 April 1939 Lagos State, Nigeria |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressives Congress |
Alma mater | University of Surrey |
Ìbèrẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ àtúnṣe
Ọjọ́ ọgbọ̀n, osù kẹrin, ọdún 1939 ni wọ́n bi. Ilé-ìwé CMS Girls School ni ó ti bẹ̀rẹ̀ ètò èkọ́ rẹ̀ kí ó tó lọ sí ilé-ìwé gíga ti ìlú Surrey, ní England lọ kàwé.[3]
Isẹ́ rẹ̀ àtúnṣe
Ó gboyè nínú ẹ̀kọ́ Journalism ní ọdún 1962. Ó sì ń ṣiṣẹ́ gégẹ́ bí akọròyìn fún BBC àti VON magazine.[4] Ní ọdún 1999, ó wọlé gẹ́gẹh bíi amúgbálẹ́gbèẹ́ gómínà Bola Tinubu, óun sí ni igbákejì gómìnà ẹlékọkànlá. Lọ́dún náà lọ́hùn-ún, òun nìkan ni obìnrin láàrin àwọn olóṣèlú tó wà nínú ìṣèjọba.[5]
Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe
- ↑ "‘The greatest lesson life has taught me at 70’ -Kofoworola Bucknor-Akerele". Encomium. 28 December 2015. http://encomium.ng/the-greatest-lesson-life-has-taught-me-at-70-kofoworola-bucknor-akerele/.
- ↑ Femi Okurounmu (6 April 2010). Leadership Failure and Nigeria's Fading Hopes: Being excerpts from PATRIOTIC PUNCHES a weekly column in the Nigerian Tribune from 2004 – 2009. AuthorHouse. pp. 231–. ISBN 978-1-4490-8410-3. https://books.google.com/books?id=WxNclw-NgU4C&pg=PA231.
- ↑ S. J. Timothy-Asobele (2004). The Producer of Our Time. Upper Standard Publications. ISBN 978-978-36946-6-8. https://books.google.com/books?id=L9lkAAAAMAAJ.
- ↑ "They labelled me military mole in NADECO for nothing Bucknor Akerele". Vanguard Newspaper. Retrieved 16 July 2016.
- ↑ "Dailytrust News, Sports and Business, Politics". Daily Trust. Retrieved 2022-05-24.