Victor Akolade Olowu (tí wọ́n bí ní ọjọ́ 8, oṣù October, ọdún 1992) jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Naijiria tó ń ṣịṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi agbóhùnsáfẹ́fẹ́ àti oníṣòwò orí ẹ̀rọ ayélujára, tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Kolade, Mr Dominate.[1]

Kolade Dominate Olowu

Ìgbésí ayé rẹ̀ àtúnṣe

Wọ́n bi ní ọjọ́ kẹjọ oṣù kẹwàá, ọdún 1992 ní ìlú Ijebu, ipinle Ogun ní orílẹ̀-ede Naijiria. Ó lọ sí ilé-ìwé Mayflower School, ní Ikenne fún ilé-ìwé girama rẹ̀, ó sì tè síwájú si láti kẹ́kọ̀ọ́ nínú ìgbé-ìwádìí-jáde ní Federal Radio Corporation of Nigeria.

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe