Mary Mitchell Slessor (Ọjọ́ kejì oṣù kejìlá ọdún 1848 si ọjọ́ kẹtàlá oṣù kínní ọdún 1915) jẹ ajihinrere si orílẹ̀-èdè Naijiria lati ilu Scotland. Ní kété tí o dé orílẹ̀-èdè Naijiria, Slessor bẹ̀rẹ̀ si kọ èdè Efik, ti o jẹ́ èdè ìbílẹ̀ níbẹ̀. Nítorí ìmò ti o ni nipa èdè ìbílẹ̀ yi ati ìsẹ̀dá rẹ gẹ́gẹ́ bi ẹni ti o nígbo'yà, Slessor rí ojú rere àwon ará ìlú náà o si rọrùn fun un lati tan ẹsin ọmọ lẹyin Kristi ka ti o si tun ni anfani lati ṣe agbatẹru ẹtọ àwon obìnrin àti àmójútó àwon ọmọde ni ilẹ̀ náà. Ohun ti o sọ ọ di gbajúgbajà ni bi o ṣe da aṣa pípa àwon ọmọ-ọwọ ti o jẹ ìbejì duro laarin àwon ẹ̀yà  Ibibio, ni apa gúsù-ìlà-oòrùn orílẹ̀-èdè Naijiria.

Mary Slessor
Mary Slessor
Ọjọ́ìbí2 December 1848 (1848-12-02)
Aberdeen, Scotland
Aláìsí13 January 1915(1915-01-13) (ọmọ ọdún 66)
Use Ikot Oku, Itu, Akwa Ibom State, Nigeria formally known as Calabar province.
Orílẹ̀-èdèScottish
Gbajúmọ̀ fúnChristian missionary work in Africa; promoting women's rights and rescuing children from infanticide.

[1] [2]

References àtúnṣe

  1. White, Donna (29 August 2010). "Red-hot designers hail Scots missionary for inspiring African style". The Daily Record. Retrieved 2011-09-06. 
  2. Proctor, JH. Serving God and the Empire: Mary Slessor in South-Eastern Nigeria, 1876–1915. Brill. pp. 45–61. JSTOR 1581622.