Moji Makanjuola

Oníwé-Ìròyín

Moji Makanjuola jẹ́ ogbontarigi oniroyin àti agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ni Nàìjíríà.[1][2] Òun ni adarí tẹ́lẹ̀ fún ẹgbẹ́ àwọn oniroyin obìnrin ni Nàìjíríà (NAWOJ).[3][4] Wọ́n bíi Moji sì ilẹ̀ Kwara, ó sì jẹ ìkan laarin awọn oniroyin tí ó dá sí ìgbà sókè ìròyìn ni orílẹ̀ èdè Nàìjíríà pàápàá jù lọ ní eka ìròyìn nípa ìlera.[5] Òun ni olumoran media fún àwọn obìnrin UN.[6] Ó si ṣẹ́ pelu Nigeria Television Authority (NTA) kí ó tó di adarí ni èka ìlera. Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ ni Center for Disease Control, ní USA.[7]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Moji Makanjuola’s day of joy". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 6 October 2014. Retrieved 30 September 2014.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "New Telegraph – Service chiefs, eight governors, others make National Honours list". Archived from the original on 6 October 2014. Retrieved 30 September 2014.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. http://allafrica.com/stories/200702260564.html
  4. "Moji makanjuola: I never lied for government - The Sun News". The Sun News. Retrieved 30 September 2014. 
  5. "First Lady pledges increased advocacy for women’s health". Archived from the original on 30 September 2014. Retrieved 30 September 2014.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  6. "Towards restoring peace in Northern Nigeria through women". Daily Independent, Nigerian Newspaper. Retrieved 30 September 2014. 
  7. "The Challenge Judges - The African Story Challenge". Archived from the original on 6 October 2014. Retrieved 30 September 2014.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)