Nahzeem Olúfẹ́mi Mímìkò

Nahzeem Olúfẹ́mi Mímìkò tí wọ́n bí ní ọjọ́ Kíní oṣù Karùn ún ọdún 1960, jẹ́ onímọ̀ nípa ètò ẹ̀kọ́ àti alákòóso àgbà tẹ́lẹ̀ rí ilé-ẹ̀kọ́ Yunifásítì Adékúnlé Ajáṣin,[1] tí ó jẹ́ ilé-ẹ̀kọ́ ti Ìpínlẹ̀ Òndó ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ilé-ẹ̀kọ́ àgbà tí àjọ tí United State Transparency International Standard (USTIS) sọ wípé ó wà lára àwọn ilé-ẹ̀kọ́ tó peregedé jùlọ ní ọdún 2014, lásìkò ìṣàkóso Fẹmi Mímìkò.[2] Olúfẹ́mi Mímìkò nìkan ni ó jẹ́ alákòóso àgbà ilé-ẹ̀kọ́ Fásitì tí wọ́n yàn lọ síbi ìjíròrò àpapọ̀ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tí ó wáyé lásìkò ìṣàkòso Ààrẹ Goodluck Ebele Jonathan ní ọdún 2014.[3] Ó gbs ipò àṣẹ alákòóso àgbà ilé-ẹ̀kọ́ Adékúnlé Ajáṣin ní oṣù Kíní ọdún 2010. Ó jẹ́ ọ̀kan lára ọmọ ẹgbẹ́ àjọ African and African-American Studies Associate, at Harvard University, Cambridge, MA, USA. [4]

Nahzeem Olufemi Mimiko
Vice Chancellor of Adekunle Ajasin University
In office
4 January 2010 – 4 January 2015
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí1 May 1960
Ondo State, Nigeria

Àwọn Ìtọ́ka sí àtúnṣe

  1. No alternative to democracy – Prof Mimiko, Nigeria: Vanguard News Paper, 2010, retrieved 2014-08-03 
  2. US agency ranks AAUA best varsity [sic] in Nigeria, Nigeria: Tribune News Paper, 2014, archived from the original on 2014-08-11, retrieved 2014-08-03  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. Prof. Femi Mimiko: The only VC delegate, Nigeria: The punch News paper, 2014, archived from the original on 2014-08-08, retrieved 2014-08-04  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  4. Adekunle Ajasin university Vice Chancellor Mimiko caves to pressure and reinstates ASUU leader and Members, Nigeria: Sahara Reporters, 2014, retrieved 2014-08-03