Nigerian Bar Association

Ẹgbẹ́ Nigerian Bar Association (NBA) jẹ́ ẹgbẹ́ àwọn adajọ́ tí wọ́n ní ìwé-àṣẹ lọ́rílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ ẹgbẹ́ tí wọ́n máa ń jà fún ẹ̀tọ́ ọmọ ènìyàn, ẹ̀tọ́ ìlànà òfin àti Ìjọba tó dára lórílẹ̀-èdè Nigeria.[1]

Nigerian Bar Association
Nigerian Bar Association
MottoPromoting the Rule of Law
TypeProfessional Association
Purpose/focusPromote legal professionalism
IbùdóAbuja
Official languagesEnglish
PresidentOlumide Akpata
General SecretaryJoyce Oduah
Websitenigerianbar.org.ng

Ọ̀gbẹ́ni Olumide Akpata ni Ààrẹ ẹgbẹ́ náà lọ́wọ́lọ́wọ́.[2] and the current General Secretary is Joyce Oduah.[3]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Nigerian Bar Association". Namati (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-05-26. 
  2. "Akpata, an Underdog, is New NBA President". This Day. This Day Newspaper. August 2, 2020. Retrieved August 9, 2020. 
  3. ahuchaoguizu (2020-08-08). "NBA General Secretary Elect Joyce Oduah(FICMC), Visits NBA First Female General Secretary". Nigeria News Today | True Tells Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2021-01-15. Retrieved 2020-09-02.