Obioma Paul Iwuanyanwu (tí wọ́n bí ní ọdún 1962) tí orúkọ rè ní kúkurú sì jẹ́ Obiwu, jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà tó tan mọ́ ìlú America. Ó jẹ́ òǹkòwé àti ọ̀jọ̀gbọ́n. Ó jẹ́ olùkọ́ àgbà ní Central State University.[1][2]

Obiwu
Obiwu in 2015 at Central State University
BornObioma Paul Iwuanyanwu
10 Oṣù Kẹ̀sán 1962 (1962-09-10) (ọmọ ọdún 61)
Umuahia, Abia State, Nigeria
NationalityNigerian American
Alma mater
Notable awards
  • Resolution Recognition Greene County Board of Commissioners;
  • Fellow of International School of Theory in the Humanities;
  • Phi Beta Delta Honor Society for International Scholars.

Àọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Dr. Obiwu Iwuanayanwu Reads at SUNY Oneonta | The State Times". 29 October 2014. Retrieved 31 December 2015. 
  2. http://www.oac.state.oh.us/search/writers/Writer.asp?ID=459