Okoẹrú jẹ́ ìṣe ayé àtijọ́ tí àwọn ènìyàn kan máa ń ṣe káràkátà ọmọ ènìyàn mìíràn fún àwọn alágbára tàbí àwọn òyìnbó amúnisìn. Nínú okowò ẹrú, ọmọ ènìyàn ni ọjà tí wọ́n ń tà. Wọ́n máa ń kó àwọn ènìyàn tí wọ́n tà lẹ́rú lọ ṣiṣẹ́ oko àti àwọn ìṣe líle ni ìlú òyìnbó. Àwọn tí wọ́n bá kò lẹ́rú kì í ní òmìnira kankan bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n fi wọ́n ṣiṣé ní tipátipá.[1][2][3]

Àwòrán gbígbẹ́ tó ṣe àfihàn àwọn erú pẹ̀lú ìgbèkùn ní Ilẹ̀ọba Rómù, ní Smyrna, 200 CE.

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Laura Brace (2004). The Politics of Property: Labour, Freedom and Belonging. Edinburgh University Press. pp. 162–. ISBN 978-0-7486-1535-3. https://books.google.com/books?id=osZnIiqDd4sC&pg=PA162. Retrieved May 31, 2012. 
  2. Kevin Bales (2004). New Slavery: A Reference Handbook. ABC-CLIO. p. 4. ISBN 978-1-85109-815-6. https://books.google.com/books?id=8Cw6EsO59aYC&pg=PA4. Retrieved 2016-02-11. 
  3. Shelley K. White; Jonathan M. White; Kathleen Odell Korgen (27 May 2014). Sociologists in Action on Inequalities: Race, Class, Gender, and Sexuality. SAGE Publications. p. 43. ISBN 978-1-4833-1147-0. https://books.google.com/books?id=GsruAwAAQBAJ&pg=PA43.