Ọ̀rànmíyàn

(Àtúnjúwe láti Oranyan)

Nínú ìtàn àròsọ/àtẹnudẹ́nu ilẹ̀ Yorùbá Ọ̀rànmíyan tàbí Ọ̀rányàn jẹ́ Ọba Láti Ilé-Ifẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni ó tún jẹ́ ọmọ Odùduwà. Ohun ni ìtàn àròsọ ẹnu yí sọ wípé ó dá ìlú Ọ̀yọ́ sílẹ̀. [1][2]

Ere Oranmiyan

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Babarinsa, Dare (2019-04-25). "The restless children of Oranmiyan". The Guardian Nigeria News. Retrieved 2019-11-23. 
  2. oloolutof (2017-02-24). "Oranmiyan Omoluabi Odede the first Alaafin of Oyo". Yoruba Traditional & Cultural Renaissance. Retrieved 2019-11-23.