Phillip Adedotun Ogundeji

Phillip Adédọ̀tun Ògúndèjì jẹ́ olùkó ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà [1] Ó jẹ́ olùkọ́ lítíréṣọ̀ Èdè Yorùbá ní ẹ̀ka-ẹ̀kọ́ èdá-èdè Afíríkà ní ilé-ekọ́ UI Ìbàdàn, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Púpọ̀ nínú àwọn iṣẹ́ rẹ̀ ló dá lé orí eré orí ìtàgé . Bakan náà ni ó ti gba oyè ọ̀jọ̀gbọ́n ní Yunifasitì yí.[2]


  1. "Biography, Facts, Career, Wiki, Life". peoplepill.com. 2020-03-23. Retrieved 2021-07-26. 
  2. "Linguistics and African studies Publications". UNIVERSITY OF IBADAN. Archived from the original on 2021-07-26. Retrieved 2021-07-26.