Olorì Roseline Omolará Òṣípìtàn jẹ́ aláàkóso ìṣòwò Nàìjíríà àti ọmọ ọba ilẹ̀ Yorùbá. Ó jẹ́ ààrẹ àti alága ẹgbẹ́ olómìnira ti Petroleum Marketers Association of Nigeria's Women Association. Ó sì tún jẹ́ Olùdásílẹ̀ ti First Royal Oil and Gas. Òun ló mú oyè ti yèyé ọba ti ìlú ìtori dání.

Ìgbésí Ayé àtúnṣe

Wọ́n bí Olòrì Roseline Omolará Òṣípìtàn ní ìpínlẹ̀ Òǹdó ti ilẹ̀ Nàìjíríà. Òṣípìtàn ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bí alákòóso ìṣòwò ní ilé - iṣẹ́ epo ni ilẹ̀ Nàìjíríà níbi tí ó tí jẹ́ lára alága obìnrin alákọ̀ọ́kọ́. Ó jẹ́ aya Ọmọba Bọ́la Òṣípìtàn[1][2] [3] [4] [4]

Àwọn Ìtọ́ka Sí àtúnṣe

  1. "Roseline Osipitan shines on - The Nation". Latestnigeriannews.com. Retrieved 2018-12-09. 
  2. "Omolara Osipitan puts best foot forward". Africanewshub.com. Archived from the original on 2023-04-05. Retrieved 2022-07-11. 
  3. Audu, Adetutu (30 November 2014). "Roseline Osipitan shines on". The Nation Nigeria. Retrieved 9 December 2018. 
  4. 4.0 4.1 "The Senator Ajibola and Princess Rose Osipitan Children’s nuptial people are dying to read on this blog + Groom’s Dad is a 4th term Senator and Bride’s mum an oil baroness …How Sweet Sensation joined them together". Asabeafrioka.com. Archived from the original on 2018-08-27. Retrieved 2022-07-11.