Egbé agbá bóólù àfésè gbá okùnrin ti orílè-èdè Naijiria ni wón pe ni Super Eagles,tí wón má n se asójú orílè-èdè Naijiria nínú ìdíje bóólù àfésè gbá kakiri agbáyé,ti egbé Nigeria Football Federation (NFF) n se alákoso won.[1].

Awon Itokasi àtúnṣe

  1. "History of The SUPER EAGLES". Nigerian Finder. 2019-08-12. Retrieved 2023-02-03.