Ọmọ oba Tony Momoh (tí a bí ní ọjọ́ kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣu kẹrin ọdún 1939, tó sì kú ní ọjọ́ kínní oṣù kejì ọdún 2021)[1] jẹ́ akọ̀ròyìn Nàijíríà àti olóṣèlú kan tí ó jẹ́ Mínísítà fún Ìfitónilétí àti Àṣà Nàijíríà (láti ọdún 1986 wọ 1990) lákòókò ìjọba ológun ti Ọ̀gágun Ibrahim Babangida.

Prince Tony Momoh
Minister of Information and Culture
In office
1986–1990
Arọ́pòAlex Akinyele
Chairman, Congress for Progressive Change
In office
January 2011 – 1 February 2021
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí(1939-04-27)27 Oṣù Kẹrin 1939
Auchi, Colonial Nigeria
Aláìsí1 February 2021(2021-02-01) (ọmọ ọdún 81)
Websitehttp://www.tonymomoh.com

Ìbí àti ẹ̀kọ́ àtúnṣe

A bí Momoh ní ọjọ́ 27 Oṣù Kẹrin ọdún 1939 ní Auchi, ìjọba ìpínlẹ̀ Edo. Ó jẹ́ ọmọ karùn-ún lé lọ́gọ́jọ (165) ti Ọba Momoh I ti Auchi.[2]

Ó lọ sí Ilé-ìwé Ìjọba Auchi (1949–1954) àti Ilé-ìwé Anglican Okpe (1954). Momoh jẹ́ Olùkọ́ni Akẹ́ẹ̀kọ́ ní Ilé-ìwé Anglican, Auchi (Oṣù kińní- Oṣù kejìlá 1955) ati Olukọni ni Ile-iwe Anglican, Ubuneke, Ivbiaro, Ijọba Ibile Owan (January 1958 - Kejìlá 1959).[3]

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Iniobong, Iwok (1 February 2021). "Life and times of Tony Momoh". BusinessDay.ng. Archived from the original on 1 February 2021.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "OBITUARY: Tony Momoh, the 165th child of Edo monarch who defended Buhari till he died". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2 February 2021. Retrieved 2021-07-09. 
  3. "Biography – Positions held before being a Journalist". Tony Momoh. Retrieved 18 June 2011.