Ugochi Nwaigwe (tí wọ́n bí ní May 3, 1993) jẹ́ agbábọ́ọ̀lù alájùsáwọ̀n ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, tí wọ́n bí sí ìlú America. Ẹgbẹ́ Yakın Doğu Üniversitesi àti Nigerian national team ló ń gbá bọ́ọ̀lù náà fún.[1]

Ugochi Nwaigwe
Yakın Doğu Üniversitesi
PositionCenter
LeagueTKBL
Personal information
Born3 Oṣù Kàrún 1993 (1993-05-03) (ọmọ ọdún 31)
NationalityAmerican/Nigerian
Listed height6 ft 3 in (1.91 m)
Career information
CollegeTemple

Iṣẹ́ tó yàn láàyò àtúnṣe

Ó kópa nínú ìdíje ti 2017 Women's Afrobasket.[2]

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. FIBA profile
  2. "Ugo NWAIGWE at the FIBA Women's Afrobasket 2017". FIBA.basketball (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-06-25.