Wale Akorede Okunnu tí a bí lọ́jọ́ karùnún oṣù kọkànlá ọdún 1967 jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèré sinimá àgbéléwò, oǹkọ̀wé ìtàn sinimá, olùdarí àti olóòtú sinimá àgbéléwò ọmọ bíbí ìlú Ògbómọ̀ṣọ́ tí wọ́n bí sí ìlú ÌbàdànÌpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lòrílẹ̀-èdè Nigeria.[1]Ó jẹ́ òṣèré adẹ́rìnínpòṣónú tí ó ti kópa nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ sinimá.

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Ogundepo, Janet (2021-05-21). "Before stardom with...’Wale Akorede". Punch Newspapers. Retrieved 2024-03-11.