Yẹmí Àlàdé

Akọrin obìnrin
(Àtúnjúwe láti Yemi Alade)

Yẹmí Eberechi Àlàdé (ọjọ́ìbí 13 March 1989), tó gbajúmọ̀ pẹ̀lú orúkọ ìkọrin rẹ̀ bíi Yẹmí Àlàdé, ni akọrin Afropop omo orilede Nàìjíríà. Ó kọ́kọ́ gbajúmọ̀ nígbà tó gbẹ̀yẹ nínú ìdíje Peak Talent Show ní ọdún 2009, ó sì gbé àwo-orin rẹ̀ "Johnny" jáde ní ọdún 2014.[1][2][3] Bábá rẹ̀ jẹ́ ọmọ Yoruba, ìyá rẹ̀ jẹ́ ará ẹ̀yà Igbo.[4]

Yemi Alade
Yemi Alade
Background information
Orúkọ àbísọYemi Eberechi Alade
Ọjọ́ìbíOṣù Kẹta 13, 1989 (1989-03-13) (ọmọ ọdún 35)
Abia State, Nigeria
Irú orin
Occupation(s)
  • Singer
  • songwriter
InstrumentsVocals
Years active2005–present
Labels
Associated acts
Websiteyemialadeofficial.com

Itokasi àtúnṣe

  1. "New, sexy singers on the loose". vanguardngr.com. Retrieved 7 September 2014. 
  2. "Yemi Alade tours Kenya". vanguardngr.com. Retrieved 7 September 2014. 
  3. "My looks have helped my career –Yemi Alade". dailyindependentnig.com. Retrieved 7 September 2014. 
  4. "How Yemi Alade Hustled Her Way To Become The Queen Of Afrobeats" (in en). The FADER. https://www.thefader.com/2016/11/09/yemi-alade-interview-tumbum-mama-africa. 

[Ẹ̀ka:Àwọn ènìyàn alààyè]]