Zainab Balogun

òṣèré Nàíjírìà

Zainab Balogun (tí a bí ní ní ọjọ́ kẹwàá oṣù kẹwàá ọdún 1989) jẹ́ Òṣeré àti agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ni ìpínlè Nàìjíríà. Ó bẹ́ẹ́rẹ̀ sì ni ṣe agbóhùnsáfẹ́fẹ́ ni ìgbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún.[1] Ó wá nínú àwọn tí òlùdásílè The J-ist TV, ní ibi tí wọ́n ti má sọ̀rọ̀ nípa àṣà ilẹ̀ Áfríkà àti àwọn ọ̀rọ̀ tí ó jọ mọ.[2] Ó ṣíṣe agbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún Ebony TV ni ibi tí ó tí ń ṣe atọkun fún eto The spot. Ó ti ṣe atọkun ètò fún Jumia Tv náà.

Zainab Balogun-Nwachukwu
Zainab Balogun in 2019
Ọjọ́ìbíZainab Balogun
Oṣù Kẹ̀wá 10, 1989 (1989-10-10) (ọmọ ọdún 34)
London, England, United Kingdom
IbùgbéLagos, Lagos State, Nigeria
London, England
Orílẹ̀-èdèBritish Nigerian
Ẹ̀kọ́Bachelor of Law (LLB) from the University of Kent in Medway
Iṣẹ́Actress, television personality, model
Ìgbà iṣẹ́2006-present

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀ àtúnṣe

Wọn bíi Zainab sì orile-ede London, ṣùgbọ́n àwọn òbí rẹ jẹ ọmọ ilẹ̀ Nàìjíríà. Ó jẹ́ ọmọ Ẹ̀gbá ni ìlú Abeokuta ni ìpínlè Ogun.[3] Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ Sacred Heart Rc Secondary School . Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga tí University of Kent ní ibi tí ó ti kà ìwé imọ òfin.[4][5] Balogun sise fún Premier Models Management ni ìgbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ́rìndínlógún gẹ́gẹ́ bí modelii. Lẹ́yìn tí ó parí ẹ̀kọ́ ìmọ̀ òfin, ó kópa nínú àwọn ère bíi Material Girls, Cocktail, The charlatans àti The Dark Knight rises . Zainab je agbóhùnsáfẹ́fẹ́ fún ilé iṣẹ́ Ebonylife TV ni ibí tí ó tí ń ṣe atọkun fún wọn. Ó ti ṣe atọkun fún ẹtọ bíi El Now, àti The spot.[6][7]

Ayé Rẹ̀ Gangan àtúnṣe

Ní oṣù kárùn-ún ọdún 2018, Balógun fẹ́ ògbẹ́ni Dikko Nwachukwu, èyí tí ó jẹ́ Olùdásílẹ̀ Jetwest Airways. Àwọn méjì yìí ṣe ìgbéyàwó ìbílẹ̀ wọn ní ọjọ́ kẹtàlá oṣù kárùn-ún, ní ìpínlẹ̀ Èkó ní Ilẹ̀ Nàìjíríà.[8]

Balogun máa ń dá àwọn àsìkò rẹ̀ láàrin London, England, àti Lagos, èyí tí ó jẹ́ Èkó ní Ilẹ̀ Nàìjíríà.

Àwọn Ẹ̀bùn Àmì Ẹ̀yẹ Rẹ̀ àtúnṣe

Ọdún Àmìn-ẹ̀yẹ Ìsọ̀rí Èsì
2013 Exquisite Lady of the Year Awards TV Presenter of the Year Gbàá
2014 Sisterhood Awards TV Presenter of the Year Gbàá
2014 All Youth Tush Awards On-Air Personality of the Year Gbàá
2014 Nigerian Broadcasters Merit Awards Sexist On-Air Personality Gbàá
2014 Exquisite Lady of the Year Award (ELOY)[9] TV Presenter of the Year Wọ́n pèé
2018 The Future Awards Africa (TFAA)[10] Prize for Acting Gbàá

Àwọn Iṣẹ́ Eré Rẹ̀ àtúnṣe

Tẹlifísàn àtúnṣe

Year Title Role Notes
2012 The Charlatans Natalia
2012 Material Girl host
2012–present EL Now host, segment producer
2012–present The Spot host
2013 Knock Knock Hawa Webseries
2014 VHS: Music Artist Wannabe Skit herself webseries
2014 Verdict Lavena Johnson webseries
2014–present Jumia TV host, associate producer
2015– Before 30 Fast Girl, Ekua
TBA The Island Teni Bowen Cole

Fíìmù àtúnṣe

Year Title Role Notes
2011 The Dark Knight Rises Dancer Featured role
2012 Cocktail Party Guest Featured role
2015 A Soldier's Story Angela Supporting
2016 The Wedding Party Wonu Supporting
Ojukokoro (Greed) Linda Supporting
2017 The Wedding Party 2 Wonu Supporting
The Royal Hibiscus Hotel Ope Lead
2018 Sylvia Sylvia Lead
Chief Daddy Ireti Supporting
God Calling Sade Lead
2021 Fine Wine Temisan
Charge and Bail Boma
2021 Chief Daddy 2: Going for Broke

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Ade-Unuigbe, Adesola. "Fab Interview: 'I Have a Little Crush on D'Banj' Zanaib Balogun, Ebony Life TV Presenter Talks Life, Love & Work". Fab Magazine Online. February 7, 2014. December 5, 2014. [1]
  2. Roosblad, Shomara. "Interview with Zainab Balogun". The Black Blog. Vogue.it. September 29, 2014. December 5, 2014. [2] Archived 2016-08-16 at the Wayback Machine.
  3. "Secret lives of Baba segis wives author Lola shoneyin & the Trio discuss attitudes & their altitudes". YouTube. Ebonylife Television. 
  4. Igew, Miles. "StyleVitae Meets - Zainab Balogun". StyleVitae. April 28, 2014. December 5, 2014. [3]
  5. ""Zippy Zainab". Our Blogazine. October 24, 2013. December 5, 2014". Archived from the original on March 8, 2016. Retrieved May 13, 2020. 
  6. Ngomba, Joan. "EbonyLife TV's Zainab Balogun Spills Secrets Behind 'The Spot'". Pulse.ng. March 19, 2014. December 5, 2014. [4]
  7. "Zainab Balogun's Interview with Zen". Zen Magazine Africa. 2013. December 5, 2014. [5]
  8. "Zainab Balogun Talks About Meeting Her Dikko Nwachukwu". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-04-05. Retrieved 2022-03-02. 
  9. "Seyi Shay, Toke Makinwa, Mo’Cheddah, DJ Cuppy, Others Nominated". Pulse Nigeria. Chinedu Adiele. Retrieved 20 October 2014. 
  10. adekunle (2018-12-17). "Simi, Zainab Balogun, Mark Angel, Ahmed Musa win at 2018 The Future Awards". Vanguard News Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2018-12-17.