Sen. Binos Dauda Yaroe jẹ́ olóṣèlú ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti Sénátọ̀ tí ó ń sójú agbègbè Adamawa South Senatorial District ti Ìpínlẹ̀ Adamawa[1] ní ilé ìgbìmò Aṣòfin àgbà lọ́wọ́lọ́wọ́.[2][3][4]

Binos Dauda Yaroe
Sénátọ̀
Lọ́wọ́lọ́wọ́June 11, 2019 títí di ìsinsìnyí
AsíwájúSen. Ahmed Abubakar Mo'Allahyidi
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbíJanuary 1, 1955
Ọmọorílẹ̀-èdèNàìjíríà
Ẹgbẹ́ olóṣèlúPeople's Democratic Party (PDP)
BàbáDauda Yaroe
ProfessionPolitician

Ìpìlẹ̀ rẹ̀ àtúnṣe

Wọ́n bí Binos Dauda Yaroe ní ọjọ́ kínní oṣù kínní ọdún 1955, ní Wagole, abúlé kan ní agbègbè Ribadu Ward ti ìjọba ìbílè Mayo-BelwaÌpínlẹ̀ Adámáwá, Nàìjíríà. Ó fẹ́ Mrs. Gimbiya Joshua, ní ọdún 1983; wọ́n bí ọmọ mẹ́rin.[5]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Senate President Ahmed Lawan praises Binos over impact of medical outreach". The Sun Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-12-09. Retrieved 2022-03-18. 
  2. "PDP Claims Adamawa South Senatorial Seat". aitonline.tv. 
  3. "APC commands Senate majority with 63 Senators, PDP behind with 44". http. March 12, 2019. 
  4. "Inconclusive Polls: Who wins Kano, Sokoto, Bauchi, Adamawa, Benue Plateau?". The Nation Newspaper. March 16, 2019. https://thenationonlineng.net/supplementary-pollswho-wins-kano-sokoto-bauchi-adamawa-benue-plateau/. 
  5. "Nigeria ScoreCard". www.nigeriascorecard.com. Archived from the original on 2021-06-28. Retrieved 2021-06-28.