Fati Abubakar jẹ́ gbajúmọ̀ oníròyìn aláwòrán àti afohùn-fawòrán ṣàgbékalẹ̀ ètò. Ó jẹ́ ọmọbìnrin ọmọ bíbí Maiduguri, ní Ìpínlẹ̀ Borno orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ni bí ti o gbajúmọ̀ dé, ìwé-ìròyìn The New York Times, CNN Africa, BBC àti Voice of America ṣe àtẹ̀jádé iṣẹ́ rẹ̀. [1]


Ìgbésí ayé àti iṣẹ́ rẹ̀ àtúnṣe

Fati jẹ ògidì ọmọ bíbí ìlú Maiduguri, ní Ìpínlẹ̀ Borno lórílẹ̀-èdè Nigeria.[2][3]

Gbajúmọ̀ àti ògidì nínú àwọn iṣẹ́ rẹ̀ ní àwọn gbankọ̀gbì àwọn ìwé ìròyìn òkè-òkun The New York Times, CNN Africa, BBC àti Voice of America tí fìgbà kan tẹ̀ jáde nínú ìwé ìròyìn wọn.[1] Ó ṣiṣẹ́ láti ṣe àgbékalè lórí làálàá àti ìṣòro tí ó dojú kọ Ìpínlẹ̀ Borno, pàápàá jù lọ, wàhálà àwọn agbésùnmọ̀mí Boko Haram. Ó ṣe iṣẹ́ kan tí ó pè ní Bits of Borno.[1][4][5]

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. 1.0 1.1 1.2 "LagosPhoto | International art festival of photography in Nigeria". LagosPhoto. Retrieved 20 April 2019. 
  2. "Fati Abubakar". africasacountry.com. Retrieved 20 April 2019. 
  3. "'She has been our family's lifeline'". Nursing Standard 31 (9): 65. 26 October 2016. doi:10.7748/ns.31.9.65.s48. ISSN 0029-6570. PMID 27787168. 
  4. "About". Bits of Borno. Archived from the original on 11 November 2020. Retrieved 20 April 2019. 
  5. "Women in war zones: Shooting the frontline when you're not a middle class man". Huck Magazine. 19 October 2018. Retrieved 20 April 2019.