Lérè Pàímọ́, OFR (tí wọ́n bí ní oṣù kọkànlá ọdún 1939) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèré, olùdarí àti olóòtú sinimá àgbéléwò ọmọ bíbí ìlú Ògbómọ̀ṣọ́, ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.[1] [2][3]

Lere Paimo
Ọjọ́ìbí(1939-11-19)19 Oṣù Kọkànlá 1939
Ogbomosho, Oyo State, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànEda Onile Ola
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
  • Actor
  • filmmaker
  • producer
  • director
Ìgbà iṣẹ́1960–present
AwardsMFR

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "People call me from everywhere to consult oracle for them –Lere Paimo". punchng.com. Archived from the original on 2015-02-08. Retrieved 2015-02-18. 
  2. "Nigeria's Top Website for News, Gossip, Comedy, Videos, Blogs, Events, Weddings, Nollywood, Celebs, Scoop and Games". Nigerian Entertainment Today. 2015-09-30. Retrieved 2019-12-17. 
  3. Adekunle, Jimoh Taofik (2019-11-20). "Ogbomosho: Elemosho, Soun and Crux of History". Republican Newspaper. Archived from the original on 2019-12-17. Retrieved 2019-12-17.