Ọlámilékan Moshood Agbélẹ̀ṣe tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Laycon ní woọ́n bí lọ́jọ́ kẹjọ oṣù kọkànlá ọdún 1993,(8 November, 1993) jẹ́ gbajúmọ̀ olùdíje tí ó borí ìdíje ètò-ìgbafẹ́ ẹ̀rọ tẹlifíṣàn, Big Brother Naija (ìpele karùn-ún), ó jẹ́ olórin-tàkasúfèé àti oǹkọ̀wé orin ọmọ orilẹ̀-èdè Nàìjíríà

Laycon
Laycon ní ICONS FEST 2021
Ọjọ́ìbíỌlámilékan Moshood Agbélẹ̀ṣe
Oṣù Kọkànlá 8, 1993 (1993-11-08) (ọmọ ọdún 30)
Ìpínlẹ̀ Èkó, Nàìjíríà
Iṣẹ́
  • Reality TV star
  • rapper
  • singer
  • songwriter
Musical career
Irú orin
InstrumentsVocals
Years active2016–present
LabelsFierce Nation
Associated acts

Ìgbésí-ayé àti ìkẹ́kọ̀ọ́ rẹ̀ láti ìbẹ̀rẹ̀ àtúnṣe

Wọ́n bí Ọlámilékan Moshood Agbélẹ̀ṣe tí gbogbo ènìyàn mọ́ sí Laycon sí ìlú Èkó, ní Nàìjíríà.[1][2] ṣùgbọ́n, ó jẹ́ ọmọ bibi ìlú Bájùwẹ̀n, ní ỌdẹdáÌpínlẹ̀ Ògùn.[3][4]

Ó kàwé gbàwé ẹ̀rí nínú ìmọ̀ philosophy ní University of Lagos lọ́dún 2012 sí 2016.[5][6][7]

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. Zawadi, Lucy. "Olamilekan "Laycon" Agbeleshe bio: BBNaija 2020 contestant profile". Legit.ng. Retrieved 28 September 2020. 
  2. Olukoya, Samuel (26 September 2020). "Laycon Bbnaija Biography, Career and Health Issue". Investors King. Retrieved 28 September 2020. 
  3. Ogunnaike, James (24 September 2020). "BBNAIJA: Ogun youths march for Laycon, give out airtime for voting". Vanguard Newspaper. Retrieved 28 September 2020. 
  4. Agbana, Rotimi (25 September 2020). "BBNAIJA: Ogun Youths Drum Support For Laycon". The Independent Newspaper. Retrieved 28 September 2020. 
  5. Adekanye, Modupeoluwa (20 July 2020). "Who is Laycon, BBNaija’s Diamond In The Rough?". The Guardian Newspaper. Retrieved 28 September 2020. 
  6. Motolani, Alake (21 July 2020). "BBNaija 2020: Who is Laycon?". Pulse Nigeria. Retrieved 28 September 2020. 
  7. Preye, Campbell (26 September 2020). "Big Brother Naija: Icons Emerge". P.M. News. Retrieved 28 September 2020.