The Guardian
Guardian logo.png
TypeDaily newspaper
FormatBroadsheet
PublisherGuardian Newspapers Limited
Founded2 February 1983; ọdún 41 sẹ́yìn (2 February 1983)
LanguageEnglish
HeadquartersLagos
Official websiteguardian.ng

The Guardian jẹ́ ìwé-ìròyìn ojoojúmọ́ olómìnira ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, tí wọ́n dá sílẹ̀ ní ọdún 1983,èyí tí Ilé-iṣẹ́ ìwé-ìròyìn Guardian tó wà ní ìpínlè Eko, ní Nàìjíríà.[1]

Ìtàn àtúnṣe

Ilé-iṣẹ́ ìwé-ìròyìn The Guardian jẹ́ dídá sílẹ̀ ní ọdún 1983 láti ọwọ́ Alex Ibru, ẹni tí ó jẹ́ oníṣòwò àti Stanley Macebuh tó jẹ́ akọ̀ròyìn pẹ̀lú ilé-iṣẹ́ ìwé-ìròyìn Daily Times ti wọ́n dá ilé-iṣẹ́ yìí sílẹ̀ láti máa ṣe àgbéjáde ìròyìn tó kúnjú òṣùwọ̀n jáde pẹ̀lú àwọn olóòtú tó jí pépé.[2] Wọ́n kọ́kọ́ ṣe àgbéjáde ìwé-ìròyìn yìí ní ọjọ́ kejìlélógún, oṣù kejì, ọdún1993 gẹ́gẹ́ bíi ìwé-ìròyìn ọ̀sọ̀ọ̀sẹ̀, tó máa ń jáde ní ọjọ́ Àìkú.[3]

Lásìkò ìṣèjọba Muhammadu Buhari, àwọn ajábọ̀-ìròyìn, ìyẹn Tunde Thompson àti Nduka Irabor ni wọ́n rán lọ sí ọgbà ẹ̀wọ̀n ní ọdún 1984 lábẹ́ ìfilélẹ̀ kẹrin ti ọdún 1984, èyí tẹrí òmìnira àwọn akọ̀ròyìn mọ́lẹ̀.[4][5]

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "The Guardian". JournalSeek. Retrieved 14 May 2011. 
  2. Linda K. Fuller (2004). National Days/National Ways: Historical, Political, and Religious Celebrations Around the World. Greenwood Publishing Group. p. 171. ISBN 0-275-97270-4. https://books.google.com/books?id=llmCOvtWcUcC&pg=PA171. 
  3. "With The Guardian, Alex Ibru came, saw and conquered". The Guardian (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-07-04. Retrieved 2022-05-23. 
  4. Stanley Mokaogwu (19 March 2011). "Investigative Journalism: A Panacea For Corruption". Nigerian Observer. Archived from the original on 24 March 2011. Retrieved 14 May 2011.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  5. Omomia, Kassim (20 April 2011). "Buhari And The Subtle, "No Court Declaration"". Nigerian Pilot. Retrieved 14 May 2011.