Chinonso Obinna Amadi[1] (tí wọ́n bí ní September 1, ọdún 1995) jẹ́ olórin orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, akọrinkalẹ̀ àti agbórinjáde.[2] Ó jẹ́ olórin tó kọ́ ara rẹ̀ níṣẹ́ orin kíkọ, àti bí wọ́n ṣe ń gbórinjáde. Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ yìí nígbà tí ó wá ní ilé-ẹ̀kọ́ gíga ti Covenant University, níbi tí ó ti kọ́ ẹ̀kọ́ nípa.[3]

Nonso Amadi
Amadi in 2018
Amadi in 2018
Background information
Orúkọ àbísọChinonso Obinna Amadi
Ọjọ́ìbíOṣù Kẹ̀sán 1, 1995 (1995-09-01) (ọmọ ọdún 28)
Lagos, Nigeria
Irú orin
Occupation(s)
  • Singer
  • songwriter
  • Record Producer
Years active2012 - present
LabelsUniversal Music Canada
Associated acts
Websitenonsoamadi.com

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "IN THE NIGHT FEAT NONSO AMADI". ASCAP. American Society of Composers, Authors and Publishers. Retrieved July 10, 2023. 
  2. Ekemezie, Henry. "Singer, Nonso Amadi drops video for No Crime | The Guardian Nigeria News - Nigeria and World NewsSaturday Magazine — The Guardian Nigeria News – Nigeria and World News". Guardian.ng. Retrieved 2019-05-25. 
  3. "About". Nonso Amadi. 2023-04-06. Retrieved 2023-06-01.