Olasope O. Oyelaran jẹ́ ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti ọ̀jọ̀gbọ́n ìmọ̀ ẹ̀dá-èdè[1] ní ẹ̀ka-ẹ̀kọ́ èdè àti lítíréṣọ̀ Áfíríkà ní ilé-ẹ̀kọ́ Yunifásitì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀, ní Ilé-Ifẹ̀. Láti ìgbà tí wọ́n ti dá ẹ̀ka-ẹ̀kọ́ yìí sílẹ̀ ní ọdún 1975 ó ti wà ní ibẹ̀. Kí ó tó di àsìko ̀ yí, ó ti ń ṣiṣẹ́ ní Institute of African Studies, OAU, Ifẹ̀ láti ọdún 1970. Òun ni olùkọ́ àkọ́kọ́ ní ẹ̀ka-ẹ̀kọ́ èdè àti Lítíréṣọ̀ Afirika, OAU. Ó fẹ̀yìn tì lẹ́nu iṣẹ́ olùkọ́ni ní ọdún 1988.[2]



Àwọn ìtọ́ka sí àtúnṣe

  1. "African Books Collective: Olasope O. Oyelaran". African Books Collective. Retrieved 2021-07-26. 
  2. "Olasope O Oyelaran books and biography". Waterstones. Retrieved 2021-07-26.