Oluremi Oyo

Oníwé-Ìròyín

Oluremi Oyo (bíi ni ọjọ́ kejìlá oṣù kẹwàá ọdún1962, o kú ní ọjọ́ kìíní oṣù kẹwàá ọdún 2014) jẹ́ ogbontarigi oníróyìn àti adarí tẹ́lẹ̀ fún ẹgbẹ́ àwọn oniroyin ni Nàìjíríà. Òun ni oluranlọwọ pàtàkì fún olórí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ni ọdún 2003, Olusegun Obasanjo lórí àwọn ọ̀rọ̀ ìkéde, òun sì ni obìnrin àkọ́kọ́ tí ó má de ipò naa.[1][2]

Oluremi Oyo
Managing Director of the News Agency of Nigeria
In office
July 2007 – 2013
Arọ́pòIma Niboro
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí12 October 1952
Ilorin Kwara State Nigeria
Aláìsí1 October 2014(2014-10-01) (ọmọ ọdún 61)
United Kingdom
Ẹgbẹ́ olóṣèlúNon-Partisan

Iṣẹ́ àtúnṣe

O lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga tí University of Lagos níbi tí ó tí gboyè nínú èrọ ibaraenisọrọ àti ìròyìn.[3] O gboyè masters nínú International relations ni ilé ẹ̀kọ́ gíga tí University of Kent ni orílẹ̀ èdè United Kingdom.[4] Oluremi bẹẹrẹ̀ iṣẹ́ gẹ́gẹ́ bíi oniroyin ni ọdún 1973 ni Nigerian Broadcasting Corporation tí ó ti wà yí orúkọ padà sii Federal Radio Corporation of Nigeria (FRCN). Ó darapọ̀ mọ́ NAN ni 1981 gẹ́gẹ́ bíi alatunse ìròyìn, ó sì kúrò ní ọdún 1985. Ó ti si ṣé fún Inter Press Service News Agency àti International news agency. Ní ọdún 1998, Gen. Abdulsalami Abubakar fi ṣe ìkan laarin awon ti o se ofin fún Nàìjíríà. Ó di oluranlọwọ pàtàkì àgbà fún Olusegun Obasanjo ni ọdún 2003 ló rí ọ̀rọ̀ ìkéde. Ó di adarí fún ẹgbẹ́ àwọn oniroyin tí Nàìjíríà ni oṣù keje ọdún 2007.[5][6][7][8] Ó kú ní orílẹ̀ èdè United Kingdom ni ọjọ́ kìíní oṣù kẹwàá ọdún 2014. Àrùn jẹjẹrẹ ni ó pá.[9][10][11] Wọn sín sí itẹ̀ àwọn òkú ní Yaba ni ìpínlè Èkó.[12] O gba Ẹ̀bùn láti National Council of Catholic Women Organisation of Nigeria merit award[13] àti national award of Officer of the Order of Niger, OON, ni odun 2006. Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ Nigerian Guild of Editors (NGE), Nigerian Institute of Management (NIM), Nigerian Institute of Public Administrators àti Nigerian Guild of Editors.[14][15]

Àwọn Ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Former Managing Director of NAN, Oluremi Oyo Is Dead ‹ International Centre for Investigative Reporting". Retrieved 4 October 2014. 
  2. siteadmin (2014-10-02). "Former President Obasanjo’s spokesperson, Remi Oyo, Dies At 62 | Sahara Reporters". Sahara Reporters. http://saharareporters.com/2014/10/02/former-president-obasanjo%E2%80%99s-spokesperson-remi-oyo-dies-62. 
  3. "Jonathan, Obasanjo, Mark, others extol Remi Oyo's Virtues, Mourn her". Thisday. Archived from the original on 2015-04-11. https://web.archive.org/web/20150411002934/http://www.thisdaylive.com/articles/jonathan-obasanjo-mark-others-extol-remi-oyo-s-virtues-mourn-her-passing/190453/. 
  4. "Former President Obasanjo’s spokesperson, Remi Oyo, Dies At 62". Sahara Reporters. October 2, 2014. 
  5. "IRIN Africa - LIBERIA-SIERRA LEONE: Interpol warrant for Taylor illegal, says defence lawyer - Liberia - Sierra Leone - Conflict". IRINnews. Retrieved 4 October 2014. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  6. "BBC NEWS - Africa - Nigeria rules out Taylor arrest". http://news.bbc.co.uk/1/hi/world/africa/3293613.stm. Retrieved 4 October 2014. 
  7. "Mum was the force that held us together – Oluremi Oyo’s son". 
  8. "Oluremi Oyo, former News Agency of Nigeria boss dies - Premium Times Nigeria". October 2, 2014. 
  9. "Remi Oyo is dead". The Sun. October 3, 2014. http://www.sunnewsonline.com/new/?p=84406m. Retrieved November 14, 2014. 
  10. "My last moment with Remi Oyo in UK hospital – Nephew :: The Nation". Archived from the original on 6 October 2014. Retrieved 4 October 2014. 
  11. "President Jonathan Mourns Ex-Nan Boss, Remi Oyo". Archived from the original on 6 October 2014. Retrieved 4 October 2014.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  12. "Tears, tributes as Remi Oyo is buried in Lagos". The Sun. October 25, 2014. Retrieved November 14, 2014. 
  13. "Former Obasanjo's Media Aide, Oluremi Oyo Dies Of Cancer In UK". African Examiner. 2 October 2014. Retrieved 22 May 2020. 
  14. "Remi Oyo’s Death: Another blow to the Media – IPC – Nigerian Democratic Report". 
  15. "Mrs. Oluremi Oyo".