Sinach

Akọrin obìnrin

Osinachi Kalu Okoro Egbu,[1] Tí a mọ̀ gẹ́gẹ́ bí Sinach, àbí ní ọjọ́ ọgbọ́n oṣù kẹta ọdún 1972. Ó jẹ́ olórin ìlú Nàìjíríà, akọrin àti olórí olùsìn àgbà tí ó tí ń ṣiṣẹ́ fún bí ọgbọ́n ọdún.[2][3] Ó jẹ́ akọrin àkókò tó kọ́kọ́ de ipò Billboard Christian Songwriter chart fún ọ̀sẹ̀ méjìlá.[4] Ẹ̀mẹ́ta ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ní Wọ́n yan orin rẹ̀ ó sì gba orin tó dára jù lọ́dún ní 5i st GMA Dove Awards, èyí ni ó jẹ́ kí ó di ọmọ Nàìjíríà àkókò tí ó gba àmì-ẹ̀yẹ.[5] Ní ọdún 2021 ó gba ìdánimọ̀ ní US congress ní ìgbà tí ó wà ní ìrìn-àjò ní United States tí Amẹ́ríkà.[6][7]

Sinach
Sinach in Johannesburg, 2016
Sinach performing at Mosaiek Theatre in Johannesburg 2016
Background information
Orúkọ àbísọOsinachi Kalu
Ọjọ́ìbí30 Oṣù Kẹta 1972 (1972-03-30) (ọmọ ọdún 52)
Ìbẹ̀rẹ̀Afikpo South, Ebonyi State, Nigeria
Irú orin
Occupation(s)
  • Singer
  • songwriter
  • worship leader
InstrumentsVocals
Years active1994–present
Labels
  • Loveworld
  • SLIC
Website

Àwọn ìtọ́kasí àtúnṣe

  1. "Dove Awards name for King & Country top artist". ABC News. 
  2. "Who is Sinach". Daily Media. DailyMedia Nigeria. 26 May 2016. Archived from the original on 26 December 2017. Retrieved 26 September 2017. 
  3. "Sinach". 9999CarolSingers. Archived from the original on 6 June 2014. Retrieved 3 June 2014. 
  4. Clarks, Jessie (5 June 2020). "Sinach Named Top Christian Songwriter For Twelve Weeks In A Row". TheChristianBeat.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 16 December 2020. 
  5. "2020 Dove Awards: Sinach's Way Maker emerges song of the Year". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 3 November 2020. Retrieved 27 March 2021. 
  6. "Sinach gets US Congress recognition". Businessday NG (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-10-04. Retrieved 2021-10-04. 
  7. "Sinach teams up with friends for annual concert" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2021-10-04. Retrieved 2021-10-04 – via ((The_Punch )).